Publicidade

João 7

Jesu lọ àjọ ìpàgọ́

1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí Jesu ń rìn Galili, nítorí fẹ́ rìn Judea, nítorí àwọn Júù ń a láti pa. 2 7.2: Le 23.34; De 16.16.Àjọ àwọn Júù í ṣe àjọ àgọ́ súnmọ́ etílé tan. 3 7.3: Mk 3.21,31; Mt 12.46.Nítorí náà, àwọn arákùnrin rẹ̀ fún un , "Lọ kúrò níhìn-ín yìí, o lọ Judea, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ pẹ̀fi iṣẹ́ rẹ hàn fún aráyé. 4 Nítorí ẹnikẹ́ni í ṣe ohunkóhun níkọ̀kọ̀, òun tìkára rẹ̀ ń fẹ́ a mọ òun gbangba. ìwọ ń ṣe nǹkan wọ̀nyí, fi ara rẹ hàn fún aráyé." 5 Nítorí àwọn arákùnrin rẹ̀ pàápàá tilẹ̀ gbà á gbọ́.

6 7.6: Mt 26.18; Jh 2.4; 7.30. Nítorí náà ni Jesu fún wọn , "Àkókò gan an fún mi ì ; fún ̀yin, gbogbo àkókò ni ó dára fún yín. 7 7.7: Jh 15.18-21.Ayé kórìíra yín; ṣùgbọ́n èmi ni ó kórìíra, nítorí mo jẹ́rìí gbé é , iṣẹ́ rẹ̀ burú. 8 ̀yin gòkè lọ àjọ yìí, èmi yóò ì gòkè lọ àjọ yìí; nítorí àkókò mi ì ì ." 9 Nígbà ó ti sọ nǹkan wọ̀nyí fún wọn tan, ó dúró Galili síbẹ̀.

10 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn arákùnrin rẹ̀ gòkè lọ tan, nígbà náà ni òun gòkè lọ àjọ náà pẹ̀, í ṣe gbangba, ṣùgbọ́n ẹni níkọ̀kọ̀. 11 Nígbà náà ni àwọn Júù ń a kiri nígbà àjọ , "Níbo ni ó ?"

12 7.12: Jh 7.40-43. Ìkùnsínú púpọ̀ láàrín àwọn ìjọ ènìyàn nítorí rẹ̀, nítorí àwọn kan , "Ènìyàn rere í ṣe."

Àwọn mìíràn , "Bẹ́̀ kọ́, ṣùgbọ́n òun ń tan ènìyàn jẹ ni." 13 7.13: Jh 19.38; 20.19.Ṣùgbọ́n ẹnìkan ó sọ̀rọ̀ rẹ̀ gbangba nítorí ìbẹ̀àwọn Júù.

Jesu kọ́ àwọn ènìyàn

14 Nígbà àjọ àárín; Jesu gòkè lọ tẹmpili ó ń kọ́ni. 15 Ẹnu ya àwọn Júù, wọ́n , "Ọkùnrin yìí ti ṣe mọ ìwé, nígbà kọ́ ̀kọ́?"

16 Jesu dáhùn, ó , "̀kọ́ mi í ṣe tèmi, ṣe ti ẹni ó rán mi. 17 ẹnikẹ́ni fẹ́ láti ṣe ìfẹ́ rẹ̀ yóò mọ̀ ti ̀kọ́ náà, ìbá ṣe ti Ọlọ́run, tàbí èmi sọ ti ara mi. 18 Ẹni ń sọ ti ara rẹ̀ ń ògo ara rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹni ń ògo ẹni ó rán an, òun ni olóòtítọ́, àìṣòdodo nínú rẹ̀. 19 7.19: Jh 1.17.Mose ha fi òfin fún yín, ẹnikẹ́ni nínú yín ó pa òfin náà mọ́? Èéṣe ̀yin fi ń ̀láti pa ?"

20 7.20: Jh 8.48; 10.20; Mt 11.18; Mk 3.22. Ìjọ ènìyàn dáhùn, wọ́n , "Ìwọ ̀èṣù, ta ni ń ̀láti pa ́?"

21 7.21: Jh 5.2-9. Jesu dáhùn ó fún wọn , "Kìkì iṣẹ́ àmì kan ni mo ṣe, ẹnu ya gbogbo yín. 22 7.22: Le 12.3; Gẹ 17.10; 21.4.Síbẹ̀, nítorí Mose fi ìkọlà fún yín (tilẹ̀ kúkú láti ̀dọ̀ Mose ṣe láti ̀dọ̀ àwọn baba ńlá yín); nítorí náà ń kọ ènìyàn ilà ọjọ́ ìsinmi. 23 7.23: Mk 3.5; Lk 13.12; 14.4.ènìyàn ń gba ìkọlà ọjọ́ ìsinmi, a ba à òfin Mose, ha ti ṣe ń bínú mi, nítorí mo ènìyàn kan láradá ọjọ́ ìsinmi? 24 7.24: Jh 8.15; Isa 11.3; Sk 7.9.ṣe ìdájọ́ nípa ti ara, ṣùgbọ́n máa ṣe ìdájọ́ òdodo."

Ṣé Jesu ni Kristi?

25 Nígbà náà ni àwọn kan nínú àwọn ará Jerusalẹmu , "Ẹni wọ́n ń ̀láti pa kọ́ yìí? 26 ó, ó ń sọ̀rọ̀ gbangba, wọn nǹkan kan i. Àwọn olórí ha mọ̀ nítòótọ́ , èyí ni Kristi náà? 27 7.27: Jh 6.42; 7.41; 9.29.Ṣùgbọ́n àwa mọ ibi ọkùnrin gbé ti , ṣùgbọ́n nígbà Kristi , ẹni yóò mọ ibi ó gbé ti ."

28 7.28: Jh 8.42. Nígbà náà ni Jesu kígbe tẹmpili ó ti ń kọ́ni, , "̀yin mọ̀ , mọ ibi mo ti , èmi fún ara mi, ṣùgbọ́n olóòtítọ́ ni ẹni ó rán mi, ẹni ̀yin mọ̀. 29 7.29: Jh 8.55; 17.25; Mt 11.27.Ṣùgbọ́n èmi mọ̀ ́n, nítorí lọ́dọ̀ rẹ̀ ni mo ti , òun ni ó rán mi."

30 7.30: Jh 7.44; 10.39; Mk 12.12; Jh 8.20. Nítorí náà wọ́n ń ̀à ti un, ṣùgbọ́n ẹnìkan ó gbé ọwọ́ e, nítorí wákàtí rẹ̀ ì . 31 7.31: Jh 8.30; 10.42; 11.45.̀pọ̀ nínú ìjọ ènìyàn gbà á gbọ́, wọ́n , "Nígbà Kristi náà , yóò ha ṣe iṣẹ́ àmì wọ̀nyí, ọkùnrin yìí ti ṣe lọ?"

32 Àwọn Farisi gbọ́ , ìjọ ènìyàn ń sọ nǹkan wọ̀nyí lábẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀; àwọn Farisi àti àwọn olórí àlùfáà rán àwọn oníṣẹ́ lọ láti un.

33 7.33: Jh 8.21; 12.35; 13.33; 14.19; 16.16-19. Nítorí náà Jesu fún wọn , "Níwọ́n ìgbà díẹ̀ ni èmi yóò pẹ̀yín, èmi yóò lọ ̀dọ̀ ẹni ó rán mi. 34 ̀yin yóò mi, ̀yin yóò mi, àti ibi èmi , ̀yin yóò le ."

35 7.35: Jk 1.1; 1Pt 1.1; Jh 12.20; Ap 11.20. Nítorí náà ni àwọn Júù ń ara wọn sọ , "Níbo ni ọkùnrin yìí yóò gbé lọ àwa yóò fi i? Yóò ha lọ àárín àwọn Helleni wọ́n fọ́n káàkiri, ó máa kọ́ àwọn Helleni . 36 ̀rọ̀ kín ni èyí ó sọ yìí, ̀yin yóò mi, yóò mi, àti Ibi èmi ̀yin yóò le ?"

37 7.37: Le 23.36; Jh 4.10,14. Lọ́jọ́ kẹ́yìn, í ṣe ọjọ́ ńlá àjọ, Jesu dúró, ó kígbe , "òǹgbẹ ń gbẹ ẹnikẹ́ni, ó tọ̀ , ó mu. 38 7.38: Isa 44.3; 55.1; 58.11.Ẹnikẹ́ni ó gbà gbọ́ gẹ́gẹ́ Ìwé Mímọ́ ti , láti inú rẹ̀ ni odò omi ìyè yóò ti máa sàn jáde ." 39 7.39: Jh 20.22; 12.23.Ṣùgbọ́n ó sọ èyí ti ̀, àwọn ó gbà á gbọ́ ń bọ̀ gbà, nítorí a ì fi Èmí Mímọ́ fún ni; nítorí a ì ṣe Jesu lógo.

40 7.40: Jh 1.21; Mt 21.11. Nítorí náà, nígbà ̀pọ̀ nínú ìjọ ènìyàn gbọ́ ̀rọ̀ wọ̀nyí, wọ́n , "Lóòótọ́ èyí ni wòlíì náà."

41 Àwọn mìíràn , "Èyí ni Kristi náà."

Ṣùgbọ́n àwọn kan kínla, "Kristi yóò ha ti Galili ? 42 7.42: Mt 5.2; Mt 1.1; Lk 2.4.Ìwé mímọ́ ha , Kristi yóò ti inú irú-ọmọ Dafidi , àti Bẹtilẹhẹmu, ìlú Dafidi ti ?" 43 Bẹ́̀ ni ìyapa láàrín ìjọ ènìyàn nítorí rẹ̀. 44 7.44: Jh 7.30; 10.39.Àwọn mìíràn nínú wọn fẹ́ láti un; ṣùgbọ́n ẹnìkan ó gbé ọwọ́ e.

Àìgbàgbọ́ àwọn adarí Júù

45 ìparí, àwọn ̀ṣọ́ tẹmpili padà tọ àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi lọ, wọ́n fún wọn , "Èéṣe ̀yin fi un ?"

46 7.46: Mt 7.28. Àwọn ̀ṣọ́ dáhùn , "ẹni ó ì sọ̀rọ̀ ọkùnrin yìí !"

47 Nítorí náà àwọn Farisi wọn lóhùn , "A ha tan ̀yin jẹ pẹ̀? 48 Ǹjẹ́ nínú àwọn ìjòyè, tàbí àwọn Farisi ti gbà á gbọ́ ? 49 Ṣùgbọ́n ìjọ ènìyàn yìí, ko mọ òfin di ẹni ìfibú."

50 7.50: Jh 3.1; 19.39. Nikodemu ẹni ó tọ Jesu lóru , ó jẹ́ ̀kan nínú wọn sọ fún wọn , 51 "Òfin wa ha ń ṣe ìdájọ́ ènìyàn ó gbọ́ ti ẹnu rẹ̀ àti ó mọ ohun ó ṣe ?"

52 7.52: 2Ọb 14.25. Wọ́n dáhùn wọ́n fún un , "Ìwọ pẹ̀láti Galili ? kiri, o nítorí wòlíì kan ó ti Galili dìde."

53 Wọ́n lọ olúkúlùkù ilé rẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-