Pular para o conteúdo
Publicidade

João 7

3 7.3: Mk 3.21,31; Mt 12.46.Nítorí náà, àwọn arákùnrin rẹ̀ fún un , "Lọ kúrò níhìn-ín yìí, o lọ Judea, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ pẹ̀fi iṣẹ́ rẹ hàn fún aráyé. 4 Nítorí ẹnikẹ́ni í ṣe ohunkóhun níkọ̀kọ̀, òun tìkára rẹ̀ ń fẹ́ a mọ òun gbangba. ìwọ ń ṣe nǹkan wọ̀nyí, fi ara rẹ hàn fún aráyé." 5 Nítorí àwọn arákùnrin rẹ̀ pàápàá tilẹ̀ gbà á gbọ́.

Veja também