Pular para o conteúdo
Publicidade

Lucas 1

11 1.11: Lk 2.9; Ap 5.19. Angẹli Olúwa kan fi ara hàn án, ó dúró apá ̀tún pẹpẹ tùràrí. 12 Nígbà Sekariah i, orí rẹ̀ , ̀á. 13 1.13: Lk 1.30,60.Ṣùgbọ́n angẹli náà fún un , "bẹ̀, Sekariah: nítorí àdúrà rẹ gbà; Elisabeti aya rẹ yóò ọmọkùnrin kan fún , ìwọ ó sọ orúkọ rẹ̀ Johanu. 14 Òun yóò jẹ́ ayọ̀ àti ìdùnnú fún , ènìyàn púpọ̀ yóò yọ̀ ìbí rẹ. 15 1.15: Nu 6.3; Lk 7.33.Nítorí òun ó pọ̀ níwájú Olúwa, yóò mu ọtí wáìnì, bẹ́̀ ni yóò mu ọtí líle; yóò kún fún ̀Mímọ́ àní láti inú ìyá rẹ̀ . 16 Òun ó ènìyàn púpọ̀ padà nínú àwọn ọmọ Israẹli Olúwa Ọlọ́run wọn. 17 1.17: Mt 11.14; 17.13; Ml 4.5.̀àti agbára Elijah ni Olúwa yóò fi ṣáájú rẹ̀ lọ, láti pa ọkàn àwọn baba ti àwọn ọmọ, àti ti àwọn aláìgbọ́ràn ọgbọ́n àwọn olóòtítọ́; ó le pèsè àwọn ènìyàn a múra sílẹ̀ de Olúwa."

Veja também