Publicidade

Lucas 10

Jesu rán méjìléláàádọ́rin ọmọ-ẹ̀yìn jáde

1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, Olúwa yan méjìléláàádọ́rin ọmọ-ẹ̀yìn mìíràn pẹ̀, ó rán wọn méjì méjì lọ ṣáájú rẹ̀, gbogbo ìlú àti ibi òun tìkára rẹ̀ yóò . 2 Ó fún wọn , "Ìkórè pọ̀, ṣùgbọ́n àwọn alágbàṣe nǹkan, nítorí náà bẹ Olúwa ìkórè, ó rán àwọn alágbàṣe sínú ìkórè rẹ̀. 3 ̀yín pọ̀n: ó, èmi rán yín lọ ̀dọ́-àgùntàn sáàrín ìkookò. 4 ṣe àpò, ṣe àpamọ́wọ́, tàbí bàtà: ṣe ẹnikẹ́ni lọ́.

5 "ilékílé ̀yin wọ̀, kọ́ , Àlàáfíà fún ilé yìí! 6 ọmọ àlàáfíà níbẹ̀, àlàáfíà yín yóò e: ṣùgbọ́n , yóò tún padà sọ́dọ̀ yín. 7 dúró sínú ilé náà, máa jẹ, máa mu ohunkóhun wọ́n fi fún yín, nítorí ̀alágbàṣe tọ́ i. ṣe lọ láti ilé ilé.

8 "Ìlúkílùú ̀yin wọ̀, wọ́n gbà yín, jẹ ohunkóhun a gbé ka iwájú yín. 9 àwọn aláìsàn ń bẹ nínú rẹ̀ láradá, fún wọn , Ìjọba Ọlọ́run dẹ̀dẹ̀ yín! 10 Ṣùgbọ́n ìlúkílùú ̀yin wọ̀, wọn gbà yín, nígbà ̀yin jáde ìgboro ìlú náà, ̀yin , 11 Eruku ìlú yín ó wa lẹ́sẹ̀, a gbọ̀n ́n sílẹ̀ fún yín! Ṣùgbọ́n mọ èyí , ìjọba Ọlọ́run dẹ̀dẹ̀.’ 12 Ṣùgbọ́n mo fún yín, yóò sàn fún Sodomu ọjọ́ náà, ju fún ìlú náà lọ.

13 "Ègbé ni fún ìwọ, Korasini! Ègbé ni fún ìwọ Betisaida! Nítorí ìbá ṣe a ti ṣe iṣẹ́ agbára a ṣe nínú yín, Tire àti Sidoni, wọn ìbá ti ronúpìwàdà lọ́jọ́ pípẹ́ sẹ́yìn, wọn ìbá jókòó nínú aṣọ ̀fọ̀ àti nínú eérú. 14 Ṣùgbọ́n yóò sàn fún Tire àti Sidoni nígbà ìdájọ́ fún yín lọ. 15 Àti ìwọ, Kapernaumu, a ó ha gbé ga òkè ̀run? A ó rẹ̀ ́ sílẹ̀ isà òkú.

16 "Ẹni ó gbọ́ tiyín, ó gbọ́ tèmi. Ẹni ó kọ̀ yín, ó kọ̀ mi. Ẹni ó kọ̀ mi, ó kọ ẹni ó rán mi."

17 Àwọn àádọ́rin náà fi ayọ̀ padà, , "Olúwa, àwọn ̀èṣù tilẹ̀ foríbalẹ̀ fún wa orúkọ rẹ."

18 Ó fún wọn , "Èmí Satani ṣubú mọ̀nàmọ́láti ̀run . 19 Kíyèsi i, èmí fún yín àṣẹ láti tẹ ejò àti àkéekèe mọ́lẹ̀, àti lórí gbogbo agbára ̀, ṣí ohun kan ó ti ó ṣe, yóò pa yín lára. 20 Ṣùgbọ́n ṣe yọ̀ nítorí èyí , àwọn ̀ń foríbalẹ̀ fún yín; ṣùgbọ́n kúkú yọ̀, ; a kọ̀orúkọ yín ̀run!"

21 wákàtí kan náà Jesu yọ̀ nínú ̀mímọ́ ó , "Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, Baba, Olúwa ̀run àti ayé, , ìwọ pa nǹkan wọ̀nyí mọ́ kúrò lọ́dọ̀ àwọn ọlọ́gbọ́n àti amòye, ìwọ fi wọ́n hàn fún àwọn ọmọ ọwọ́. Bẹ́̀ ni, Baba, bẹ́̀ ni ó à yẹ ojú rẹ.

22 "Ohun gbogbo ni a ti fi fún mi láti ̀dọ̀ Baba mi; ṣí ẹni ó mọ ẹni ọmọ jẹ́, ṣe Baba, àti ẹnikẹ́ni ó wu ọmọ láti fi í hàn fún."

23 Ó yípadà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ apá kan. Ó , "Ìbùkún ni fún ojú ń ohun ̀yin ń . 24 Nítorí mo fún yín, ̀pọ̀ àwọn wòlíì àti àwọn ọba ni ó ń fẹ́ láti ohun ̀yin ń , wọn wọn, àti láti gbọ́ ohun ̀yin ń gbọ́, wọn gbọ́ wọn."

Òwe aláàánú ará Samaria

25 kíyèsi i amòfin kan dìde, ó ń dán an , ó , "Olùkọ́, kín ni èmi ó ṣe èmi jogún ìyè àìnípẹ̀kun?"

26 Ó bi í , "ni a kọ sínú ìwé òfin? Báwo ni ìwọ ti á?"

27 Ó dáhùn , " ìwọ fi gbogbo àyà rẹ, àti gbogbo ọkàn rẹ, àti gbogbo agbára rẹ, àti gbogbo inú rẹ fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ; àti, Ẹnìkejì rẹ ara rẹ.’ "

28 Ó fún un , "Ìwọ́ dáhùn rere. Ṣe èyí, ìwọ ó ."

29 Ṣùgbọ́n ó ń fẹ́ láti da ara rẹ̀ láre, ó fún Jesu , "Ta ha ni ẹnìkejì mi?"

30 Jesu dáhùn ó , "Ọkùnrin kan ń ti Jerusalẹmu sọ̀kalẹ̀ lọ Jeriko, ó bọ́ ọwọ́ àwọn ọlọ́ṣà; wọ́n gbà á aṣọ, wọ́n a lọ́gbẹ́, wọ́n fi sílẹ̀ lọ àìpatán. 31 kòńgẹ́ àkókò yìí ni àlùfáà kan ń sọ̀kalẹ̀ lọ lọ́náà. Nígbà ó i ó kọjá lọ níhà kejì. 32 Bẹ́̀ náà ni ọmọ Lefi kan pẹ̀, nígbà ó ibẹ̀, ó i, ó kọjá lọ níhà kejì. 33 Ṣùgbọ́n ará Samaria kan, ó ti ń re àjò, ó ibi ó gbé ; nígbà ó i, àánú ṣe é. 34 Ó tọ̀ ́ lọ, ó di ọgbẹ́ rẹ̀, ó da òróró àti ọtí wáìnì i, ó gbé e orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ti òun tìkára rẹ̀, ó un ilé èrò, a ń ṣe ìtọ́rẹ̀. 35 Nígbà ó lọ ọjọ́ kejì, ó fi owó idẹ méjì fún olórí ilé èrò ó fún un , Máa tọ́rẹ̀; ohunkóhun ìwọ kún un, nígbà mo padà , èmi ó san án fún .

36 "Nínú àwọn mẹ́tẹ̀̀ta wọ̀nyí, ta ni ìwọ ó jẹ́ ẹnìkejì ẹni ó bọ́ ọwọ́ àwọn ọlọ́ṣà?"

37 Ó dáhùn , "Ẹni ó ṣàánú fún un ni."

Jesu fún un , "Lọ, o ṣe bẹ́̀ gẹ́gẹ́!"

ilé Marta àti Maria

38 Ó ṣe, wọ́n ti ń lọ, o wọ ìletò kan, obìnrin kan a ń Marta gbà á ilé rẹ̀. 39 Ó arábìnrin kan a ń Maria ó jókòó lẹ́bàá ẹsẹ̀ Olúwa, ó ń gbọ́ ̀rọ̀ rẹ̀. 40 Ṣùgbọ́n Marta ń ṣe ìyọnu ohun púpọ̀, ó tọ̀ ́ , ó , "Olúwa, ìwọ bìkítà ti arábìnrin mi ó fi sílẹ̀ láti máa nìkan ṣe ìránṣẹ́? fún un ó ràn lọ́wọ́."

41 Ṣùgbọ́n Olúwa dáhùn, ó fún un , "Marta, Marta, ìwọ ń ṣe àníyàn àti làálàá nítorí ohun púpọ̀. 42 Ṣùgbọ́n ohun kan ni a ṣe aláìní, Maria ti yan ipa rere náà a gbà lọ́wọ́ rẹ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-