Pular para o conteúdo
Publicidade

Lucas 21

25 21.25-27: Mt 24.29-30; Mk 13.24-26. 21.25: If 6.12-13; Isa 13.10; Jl 2.10; Sf 1.15. "Àmì yóò oorun, àti òṣùpá, àti ìràwọ̀; àti lórí ilẹ̀ ayé ìdààmú fún àwọn orílẹ̀-èdè nínú ìpayà híhó Òkun àti ìgbì omi. 26 Àyà àwọn ènìyàn yóò máa fún ìbẹ̀, àti ìrètí nǹkan wọ̀nyí ń bọ̀ sórí ayé: nítorí àwọn agbára ̀run ni a ó tìtì. 27 21.27: Lk 9.27; Da 7.13-14.Nígbà náà ni wọn ó Ọmọ Ènìyàn yóò máa bọ̀ nínú àwọsánmọ̀ pẹ̀agbára àti ògo ńlá. 28 21.28: Lk 18.7-8.Ṣùgbọ́n nígbà nǹkan wọ̀nyí bẹ̀rẹ̀ í ṣẹ, ǹjẹ́ wo òkè, gbé orí yín sókè; nítorí ìdáǹdè yín dẹ̀dẹ̀."

Veja também