Publicidade

Lucas 24

Àjíǹde náà

1 24.1-9: Mt 28.1-8; Mk 16.1-7; Jh 20.1,11-13. kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ ̀sẹ̀, àwọn obìnrin ibojì, wọ́n ìkunra olóòórùn dídùn ti wọ́n pèsè sílẹ̀ . 2 Òkúta ti kúrò ẹnu ibojì. 3 Nígbà wọ́n wọ inú rẹ̀, wọn òkú Jesu Olúwa. 4 wọ́n ti dààmú kiri níhà ibẹ̀, kíyèsi i, àwọn ọkùnrin méjì aláṣọ dídán dúró wọ́n. 5 Nígbà ̀ń wọ́n, wọ́n dojúbolẹ̀, àwọn angẹli náà bi wọ́n , "Èéṣe ̀yin fi ń alààyè láàrín àwọn òkú? 6 24.6: Lk 9.22; 13.32-33.níhìn-ín yìí, ṣùgbọ́n ó jíǹde; rántí ó ti fún yín nígbà ó Galili. 7 , A ó fi Ọmọ Ènìyàn àwọn ènìyàn ẹlẹ́ṣẹ̀ lọ́wọ́, a ó kàn án mọ́ àgbélébùú, ọjọ́ kẹta yóò jíǹde.’ " 8 Wọ́n rántí ̀rọ̀ rẹ̀.

9 Wọ́n padà ti ibojì , wọ́n ròyìn gbogbo nǹkan wọ̀nyí fún àwọn mọ́kànlá, àti fún gbogbo àwọn ìyókù. 10 24.10: Mk 16.1; Lk 8.1-3; Jh 20.2.Maria Magdalene, àti Joanna, àti Maria ìyá Jakọbu, àti àwọn mìíràn pẹ̀wọn ni àwọn ó ròyìn nǹkan wọ̀nyí fún àwọn aposteli. 11 ̀rọ̀ wọ̀nyí dàbí ìsọkúsọ lójú wọn, wọn gbà wọ́n gbọ́. 12 Nígbà náà ni Peteru dìde, ó súré lọ ibojì; nígbà ó bẹ̀rẹ̀, ó aṣọ àlà lọ́tọ̀ fúnra wọn, ó padà lọ ilé rẹ̀, ẹnu á ohun ó ṣe.

ojú ọnà Emmausi

13 kíyèsi i, àwọn méjì nínú wọn ń lọ ọjọ́ náà ìletò kan a ń Emmausi, ó jìnnà Jerusalẹmu níwọ̀n ọgọ́ta ibùsọ̀. 14 Wọ́n ń ara wọn sọ̀rọ̀ gbogbo nǹkan wọ̀nyí ó ṣẹlẹ̀. 15 Ó ṣe, wọ́n ti ń ara wọn sọ̀rọ̀, wọ́n ń ara wọn jíròrò, Jesu tìkára rẹ̀ súnmọ́ wọn, ó ń wọn rìn lọ. 16 24.16: Jh 20.14; 21.4.Ṣùgbọ́n a wọn lójú, wọn le mọ̀ ́n.

17 Ó bi wọ́n , "̀rọ̀ kín ni ̀yin ń ara yín sọ, ̀yin ti ń rìn?"

Wọ́n dúró jẹ́, wọ́n fajúro. 18 ̀kan nínú wọn, a ń Kileopa, dáhùn fún un , "Àlejò à ni ìwọ Jerusalẹmu, ìwọ mọ ohun ó ṣẹ̀ níbẹ̀ ọjọ́ wọ̀nyí?"

19 24.19: Mt 21.11; Lk 7.16; 13.33; Ap 3.22. Ó bi wọ́n , "Kín ni?"

Wọ́n fún un , "ti Jesu ti Nasareti, ẹni ó jẹ́ wòlíì, ó pọ̀ ìṣe àti ọrọ̀ níwájú Ọlọ́run àti gbogbo ènìyàn, 20 àti àwọn olórí àlùfáà àti àwọn alàgbà wa ti fi òun wọn lọ́wọ́ láti a lẹ́bi ikú, àti wọ́n ti kàn án mọ́ àgbélébùú. 21 Bẹ́̀ ni òun ni àwa ti ìrètí , òun ni ìbá Israẹli ìdè. Àti pẹ̀gbogbo nǹkan wọ̀nyí, òní ni ó di ọjọ́ kẹta nǹkan wọ̀nyí ti ṣẹlẹ̀. 22 Àwọn obìnrin kan pẹ̀nínú ẹgbẹ́ wa, wọ́n lọ si ibojì kùtùkùtù, lẹ́nu, 23 nígbà wọn òkú rẹ̀, wọ́n , àwọn ìran àwọn angẹli wọ́n , ó láààyè. 24 24.24: Jh 20.3-10.Àti àwọn kan wọ́n pẹ̀wa lọ ibojì, wọ́n i gẹ́gẹ́ àwọn obìnrin náà ti , ṣùgbọ́n òun tìkára rẹ̀ ni wọn ."

25 Ó fún wọn , "̀yin òye , yigbì àyà láti gba gbogbo èyí àwọn wòlíì ti gbọ́, 26 ha yẹ Kristi ó jìyà nǹkan wọ̀nyí ó wọ inú ògo rẹ̀ lọ." 27 24.27: Lk 24.44-45; Ap 28.23; 1Pt 1.11.Ó bẹ̀rẹ̀ láti Mose àti gbogbo àwọn wòlíì , ó túmọ̀ nǹkan fún wọn nínú ìwé mímọ́ gbogbo nípa ti ara rẹ̀.

28 24.28: Mk 6.48. Wọ́n súnmọ́ ìletò wọ́n ń lọ, ó ṣe ẹni yóò lọ iwájú. 29 Wọ́n rọ̀ ́, , "wa dúró: nítorí ó di ọjọ́ alẹ́, ọjọ́ kọjá tán." Ó wọlé lọ, ó wọn dúró.

30 24.30: Lk 9.16; 22.19. Ó ṣe, ó ti wọn jókòó ti oúnjẹ, ó àkàrà, ó súre i, ó ú, ó fi fún wọn. 31 Ojú wọn , wọ́n mọ̀ ́n, ó mọ́ wọn ojú. 32 Wọ́n ara wọn sọ , "Ọkàn wa ha gbiná nínú wa, nígbà ó ń wa sọ̀rọ̀ ó ń túmọ̀ ìwé mímọ́ fún wa!"

33 Wọ́n dìde wákàtí kan náà, wọ́n padà lọ Jerusalẹmu, wọ́n àwọn mọ́kànlá péjọ, àti àwọn ń bẹ lọ́dọ̀ wọn. 34 24.34: 1Kọ 15.5.Wọn si , "Olúwa jíǹde nítòótọ́, ó ti fi ara hàn fún Simoni!" 35 Àwọn náà ròyìn nǹkan ó ṣe ̀, àti ó ti di mọ̀ fún wọn bíbu àkàrà.

Jesu fi ara han àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀

36 24.36-43: Jh 20.19-20,27; Jh 21.5,9-13; 1Kọ 15.5; Ap 10.40-41. wọ́n ti ń sọ nǹkan wọ̀nyí Jesu tìkára rẹ̀ dúró láàrín wọn, ó fún wọn , "Àlàáfíà fún yín."

37 Ṣùgbọ́n àyà wọ́n, wọ́n wárìrì, wọ́n ṣe àwọn ̀kan. 38 Ó fún wọn , "Èéṣe ara yín lélẹ̀? Èé ti ṣe èròkerò fi ń sọ nínú ọkàn yín? 39 24.39: 1Jh 1.1.wo ọwọ́ mi àti ẹsẹ̀ mi, èmi tìkára mi ni! mímú ó nítorí iwin ẹran àti egungun lára, ̀yin ti èmi ."

40 Nígbà ó bẹ́̀ tan, ó fi ọwọ́ àti ẹsẹ̀ rẹ̀ hàn wọ́n. 41 Nígbà wọn ì gbàgbọ́ fún ayọ̀, àti fún ìyanu, ó fún wọn , "̀yin ohunkóhun jíjẹ níhìn-ín yìí?" 42 Wọ́n fún un ẹja a fi oyin . 43 Ó gbà á, ó jẹ ́ lójú wọn.

44 24.44: Lk 24.26-27; Ap 28.23. Ó fún wọn , "Wọ̀nyí ni ̀rọ̀ mo sọ fún yín, nígbà èmí ti pẹ̀yín , a láti ohun gbogbo ṣẹ, a ti kọ nínú òfin Mose, àti nínú ìwé àwọn wòlíì, àti nínú Saamu, nípasẹ̀ mi."

45 Nígbà náà ni ó ṣí wọn iyè, ìwé mímọ́ wọn. 46 24.46: Ho 6.2; 1Kọ 15.3-4.Ó fún wọn , "Bẹ́̀ ni a ti kọ̀rẹ̀, : Kristi jìyà, àti ó jíǹde ọjọ́ kẹta kúrò nínú òkú, 47 24.47: Ap 1.4-8; Mt 28.19.àti a wàásù ìrònúpìwàdà àti ìdáríjì ̀ṣẹ̀ lórúkọ rẹ̀, orílẹ̀-èdè gbogbo, bẹ̀rẹ̀ láti Jerusalẹmu lọ. 48 ̀yin ni ẹlẹ́rìí nǹkan wọ̀nyí. 49 24.49: Ap 2.1-4; Jh 14.26; 20.21-23.Èmi yóò rán ohun Baba mi ṣe ìlérí yín, ṣùgbọ́n jókòó ìlú Jerusalẹmu, títí a ó fífi agbára wọ̀ yín, láti òkè ̀run ."

Ìgòkè re ̀run

50 Ó wọn jáde lọ títí wọ́n fẹ́rẹ̀ Betani, nígbà ó gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè, ó súre fún wọn. 51 24.51: Ap 1.9-11.Ó ṣe, ó ti ń súre fún wọn, ó kúrò lọ́dọ̀ wọn, a gbé e lọ ̀run. 52 24.52-53: Ap 1.12-14.Wọ́n foríbalẹ̀ fún un, wọ́n padà lọ Jerusalẹmu pẹ̀ayọ̀ púpọ̀. 53 Wọ́n tẹmpili nígbà gbogbo, wọ́n ń fi ìyìn, àti ìbùkún fún Ọlọ́run.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-