Publicidade

Lucas 3

Johanu onítẹ̀bọmi tún ọnà náà ṣe

1 3.1: Lk 23.1; 9.7; 13.31; 23.7. ọdún kẹ́̀dógún ìjọba Tiberiu Kesari, nígbà Pọntiu Pilatu jẹ́ baálẹ̀ Judea, Herodu jẹ́ tetrarki Galili, Filipi arákùnrin rẹ̀ jẹ́ tetrarki Iturea àti ti Trakoniti, Lisania jẹ́ tetrarki Abilene, 2 3.2: Jh 18.13; Ap 4.6; Mt 26.3; Jh 11.49.Annasi òun Kaiafa ń ṣe olórí àwọn àlùfáà, nígbà náà ni ̀rọ̀ Ọlọ́run tọ Johanu ọmọ Sekariah ijù. 3 3.3-9: Mt 3.1-10; Mk 1.1-5; Jh 1.6,23.Ó gbogbo ilẹ̀ aginjù Jordani, ó ń wàásù ìtẹ̀bọmi ìrònúpìwàdà fún ìmúkúrò ̀ṣẹ̀, 4 3.4-6: Isa 40.3-5.a ti kọ ́ nínú ìwé ̀rọ̀ wòlíì Isaiah ,

"Ohùn ẹni ń kígbe ijù,

tún ̀Olúwa ṣe,

ipa ̀rẹ̀ tọ́.

5 Gbogbo ̀gbun ni a yóò kún,

gbogbo òkè ńlá àti òkè kékeré ni a ó tẹ́ pẹẹrẹ.

Wíwọ́ ni a ó ṣe títọ́,

àti ̀gbọ́ngungbọ̀ngun ni a o sọ di dídán.

6 3.6: Lk 2.30. Gbogbo ènìyàn ni yóò ìgbàlà Ọlọ́run.’ "

7 3.7: Mt 12.34; 23.33. Nígbà náà ni ó fún ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ó láti ṣe ìtẹ̀bọmi lọ́dọ̀ rẹ̀ , "̀yin ìran paramọ́lẹ̀, ta ni ó kìlọ̀ fún un yín láti kúrò nínú ìbínú ń bọ̀? 8 3.8: Jh 8.33,39.Nítorí náà ̀yin ó so èso ó yẹ fún ìrònúpìwàdà, ṣe í nínú ara yín , Àwa Abrahamu baba.èmi ó fún un yín, Ọlọ́run gbé ọmọ dìde fún Abrahamu nínú òkúta wọ̀nyí. 9 3.9: Mt 7.19; Hb 6.7-8.Àti nísinsin yìí pẹ̀, a fi àáké gbòǹgbò igi náà, gbogbo igi so èso rere, a óò ge lulẹ̀, a wọ sínú iná."

10 Àwọn ènìyàn ń bi í , "ni àwa ó ṣe?"

11 Ó dáhùn ó fún wọn , "Ẹni ó ̀méjì, ó fi ̀kan fún ẹni ; ẹni ó oúnjẹ, ó ṣe bẹ́̀ pẹ̀."

12 Àwọn agbowó òde tọ̀ ́ láti ṣe ìtẹ̀bọmi lọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n bi í , "Olùkọ́, ni àwa ó ha ṣe?"

13 Ó fún wọn , "ṣe fi agbára gbà a ti rán yín lọ mọ́."

14 Àwọn ọmọ-ogun béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀ , "Àti àwa, ni àwa ó ṣe?"

Ó fún wọn , "ṣe hùwà ipá ẹnikẹ́ni, ṣe ka ̀sùn èké ẹnikẹ́ni; òwò ̀yín yín."

15 3.15: Ap 13.25; Jh 1.19-22. àwọn ènìyàn ti ń retí, gbogbo wọn ń nínú ara wọn nítorí Johanu, òun ni Kristi tàbí òun kọ́; 16 3.16-18: Mt 3.11-12; Mk 1.7-8; Jh 1.26-27,33; Ap 1.5; 11.16; 19.4.Johanu dáhùn ó fún gbogbo wọn , "Lóòótọ́ ni èmi ń fi omi bamitiisi yín, ṣùgbọ́n ẹni ó lágbára lọ ń bọ̀, okùn bàtà ẹsẹ̀ ẹni èmi , Òun ni yóò fi ̀Mímọ́ àti iná bamitiisi yín. 17 Ẹni àtẹ rẹ̀ ń bẹ ọwọ́ rẹ̀, láti gbá ilẹ̀ ìpakà rẹ̀ mọ́ , ó alikama rẹ̀ sínú àká; ṣùgbọ́n ìyàngbò ni yóò fi iná àjóòkú sun." 18 Johanu lo oríṣìíríṣìí ̀rọ̀ púpọ̀ láti gba àwọn ènìyàn níyànjú àti láti wàásù ìyìnrere fún wọn.

19 3.19-20: Mt 14.3-4; Mk 6.17-18. Ṣùgbọ́n nígbà ti Johanu Herodu tetrarki, ó nítorí Herodia aya Filipi arákùnrin rẹ̀, àti nítorí ohun búburú gbogbo Herodu ṣe, 20 Ó fi èyí parí gbogbo rẹ̀ nígbà ó fi Johanu sínú túbú.

Ìtẹ̀bọmi àti ìtàn ìdílé Jesu

21 3.21-22: Mt 3.13-17; Mk 1.9-11; Jh 1.29-34. 3.21: Lk 5.16; 6.12; 9.18,28; 11.1; Mk 1.35. Nígbà a ṣe ìtẹ̀bọmi àwọn ènìyàn gbogbo tán, ó ṣe, a bamitiisi Jesu pẹ̀, ó ti ń gbàdúrà, ̀run ṣí sílẹ̀, 22 3.22: Sm 2.7; Isa 42.1; Lk 9.35; Ap 10.38; 2Pt 1.17.̀Mímọ́ sọ̀kalẹ̀ orí rẹ̀ àwọ̀ àdàbà, ohùn kan ti ̀run , ó , "Ìwọ ni àyànfẹ́ ọmọ mi; ẹni inú mi dùn gidigidi."

23 3.23-38: Mt 1.1-17; Gẹ 5.3-32; 11.10-26; Ru 4.18-22; 1Ki 1.1-4,24-28; 2.1-15. 3.23: Jh 8.57; Lk 1.27. Jesu tìkára rẹ̀ ń ẹni ọgbọ̀n ọdún, nígbà ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìránṣẹ́ rẹ̀ ó jẹ́ (a ti fi ) ọmọ Josẹfu,

í ṣe ọmọ Eli, 24 í ṣe ọmọ Mattati,

í ṣe ọmọ Lefi, í ṣe ọmọ Meliki,

í ṣe ọmọ Janai, í ṣe ọmọ Josẹfu,

25 í ṣe ọmọ Mattatia, í ṣe ọmọ Amosi,

í ṣe ọmọ Naumu, í ṣe ọmọ Esili,

í ṣe ọmọ Nagai, 26 í ṣe ọmọ Maati,

í ṣe ọmọ Mattatia, í ṣe ọmọ Ṣimei,

í ṣe ọmọ Josẹfu, í ṣe ọmọ Joda,

27 í ṣe ọmọ Joana, í ṣe ọmọ Resa,

í ṣe ọmọ Serubbabeli, í ṣe ọmọ Ṣealitieli,

í ṣe ọmọ Neri, 28 í ṣe ọmọ Meliki,

í ṣe ọmọ Adi, í ṣe ọmọ Kosamu,

í ṣe ọmọ Elmadamu, í ṣe ọmọ Eri,

29 í ṣe ọmọ Joṣua, í ṣe ọmọ Elieseri,

í ṣe ọmọ Jorimu, í ṣe Mattati,

í ṣe ọmọ Lefi, 30 í ṣe ọmọ Simeoni,

í ṣe ọmọ Juda, í ṣe ọmọ Josẹfu,

í ṣe ọmọ Jonamu, í ṣe ọmọ Eliakimu,

31 í ṣe ọmọ Melea, í ṣe ọmọ Menna,

í ṣe ọmọ Mattata, í ṣe ọmọ Natani,

í ṣe ọmọ Dafidi, 32 í ṣe ọmọ Jese,

í ṣe ọmọ Obedi, í ṣe ọmọ Boasi,

í ṣe ọmọ Salmoni, í ṣe ọmọ Nahiṣoni,

33 í ṣe ọmọ Amminadabu, í ṣe ọmọ Ramu,

í ṣe ọmọ Hesroni, í ṣe ọmọ Peresi,

í ṣe ọmọ Juda. 34 í ṣe ọmọ Jakọbu,

í ṣe ọmọ Isaaki, í ṣe ọmọ Abrahamu,

í ṣe ọmọ Tẹra, í ṣe ọmọ Nahori,

35 í ṣe ọmọ Serugu, í ṣe ọmọ Reu,

í ṣe ọmọ Pelegi, í ṣe ọmọ Eberi,

í ṣe ọmọ Ṣela. 36 í ṣe ọmọ Kainani,

í ṣe ọmọ Arfaksadi, í ṣe ọmọ Ṣemu,

í ṣe ọmọ Noa, í ṣe ọmọ Lameki,

37 í ṣe ọmọ Metusela, í ṣe ọmọ Enoku,

í ṣe ọmọ Jaredi, í ṣe ọmọ Mahalaleli,

í ṣe ọmọ Kainani. 38 í ṣe ọmọ Enosi,

í ṣe ọmọ Seti, í ṣe ọmọ Adamu,

í ṣe ọmọ Ọlọ́run.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-