Publicidade

Lucas 5

Ìpè àwọn ọmọ-ẹ̀yìn àkọ́kọ́

1 Ó ṣe, nígbà ìjọ ènìyàn súnmọ́ ọn láti gbọ́ ̀rọ̀ Ọlọ́run, ó dúró létí adágún Genesareti. 2 Ó ọkọ̀ méjì ti o létí adágún: èyí àwọn apẹja ti sọ̀kalẹ̀ kúrò nínú wọn, nítorí wọ́n ń fọ àwọ̀n wọn. 3 Ó wọ ̀kan nínú àwọn ọkọ̀ náà, í ṣe ti Simoni, ó bẹ̀ ́ ó í ̀yìn díẹ̀ kúrò ilẹ̀. Ó jókòó, ó ń kọ́ ìjọ ènìyàn láti inú ọkọ̀ náà.

4 ó ti dákẹ́ ̀rọ̀ sísọ, ó fún Simoni , "í ibú, o ju àwọ̀n yín ìsàlẹ̀ fún àkópọ̀."

5 Simoni dáhùn ó fún un , "Olùkọ́ni, gbogbo òru ni àwa fi ṣiṣẹ́, àwa nǹkan kan: ṣùgbọ́n nítorí ̀rọ̀ rẹ èmi ó ju àwọ̀n náà ìsàlẹ̀."

6 Nígbà wọ́n ti ṣe èyí, wọ́n ̀pọ̀lọpọ̀ ẹja: àwọ̀n wọn ya. 7 Wọ́n pe àwọn ẹgbẹ́ wọn, ó nínú ọkọ̀ kejì, wọn ó ràn wọ́n lọ́wọ́. Wọ́n , wọ́n ẹja ọkọ̀ méjèèjì kún, bẹ́̀ ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ í .

8 Nígbà Simoni Peteru i, ó wólẹ̀ lẹ́bàá eékún Jesu, ó , "Lọ kúrò lọ́dọ̀ mi Olúwa; nítorí ẹlẹ́ṣẹ̀ ni ." 9 Ẹnu wọ́n, àti gbogbo àwọn ń bẹ pẹ̀rẹ̀, fún àkópọ̀ ẹja wọ́n , 10 bẹ́̀ ni Jakọbu àti Johanu àwọn ọmọ Sebede, ń ṣe alábákẹ́gbẹ́ Simoni.

Jesu fún Simoni , "bẹ̀; láti ìsinsin yìí lọ ìwọ ó máa ènìyàn." 11 Nígbà wọ́n ti ọkọ̀ wọn ilẹ̀, wọ́n fi gbogbo rẹ̀ sílẹ̀, wọ́n tọ̀ ́ lẹ́yìn lọ.

Ọkùnrin pẹ̀̀tẹ̀

12 Ó ṣe, nígbà Jesu wọ ̀kan nínú àwọn ìlú náà, kíyèsi i, ọkùnrin kan ̀tẹ̀ wa síbẹ̀: nígbà ó Jesu, ó wólẹ̀, ó ń bẹ̀ ́, , "Olúwa, ìwọ fẹ́, ìwọ sọ di mímọ́."

13 Jesu na ọwọ́ rẹ̀, ó fi kàn án, ó , "Mo fẹ́, ìwọ di mímọ́!" Lójúkan náà ̀tẹ̀ fi í sílẹ̀ lọ.

14 Ó kìlọ̀ fún u , "ó ṣe sọ fún ẹnìkan: ṣùgbọ́n ó lọ, ó fi ara rẹ̀ hàn fún àlùfáà, ó ta ọrẹ fún ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀, gẹ́gẹ́ Mose ti pàṣẹ gẹ́gẹ́ bi ̀fun wọn."

15 Ṣùgbọ́n òkìkí rẹ̀ ń kàn kálẹ̀: bẹ́̀ ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn jùmọ̀ pàdé láti gbọ́ ̀rọ̀ rẹ̀, àti láti gba ìwòsàn lọ́dọ̀ rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ àìlera wọn. 16 Ṣùgbọ́n lọ́pọ̀ ìgbà ni Jesu a máa yẹra kúrò si ibi ìdákẹ́rọ́rọ́, òun á máa láti gbàdúrà.

Jesu wo arọ sàn

17 ọjọ́ kan, ó ti ń kọ́ni, àwọn Farisi àti àwọn amòfin jókòó pẹ̀rẹ̀, àwọn ó ti àwọn ìletò Galili gbogbo, àti Judea, àti Jerusalẹmu : agbára Olúwa ń bẹ pẹ̀rẹ̀ láti wọn láradá. 18 à kíyèsi i, àwọn ọkùnrin kan gbé ẹnìkan ó ààrùn ̀gbà lórí àkéte: wọ́n ń ̀àti gbé e wọlé, àti láti tẹ́ síwájú Jesu. 19 Nígbà wọn ̀wọn ìbá fi gbé e wọlé nítorí ìjọ ènìyàn, wọ́n gbé e gun òkè àjà ilé lọ, wọ́n sọ̀ ́ kalẹ̀ àárín èrò ti òun ti àkéte rẹ̀ níwájú Jesu.

20 Nígbà ó ìgbàgbọ́ wọn, ó , "Ọkùnrin yìí, a darí ̀ṣẹ̀ rẹ ́."

21 Àwọn akọ̀àti àwọn Farisi bẹ̀rẹ̀ í gbèrò , "Ta ni eléyìí ń sọ ̀rọ̀-òdì? Ta ni ó dárí ̀ṣẹ̀ ji ni ṣe Ọlọ́run nìkan ṣoṣo."

22 Jesu mọ èrò inú wọn, ó dáhùn ó fún wọn , "Èéṣe fi ń ro nǹkan wọ̀nyí nínú ọkàn yín? 23 Èwo ni ó : láti , A dárí ̀ṣẹ̀ rẹ ́,’ tàbí láti , Dìde ìwọ máa rìn? 24 Ṣùgbọ́n ̀yin mọ̀ Ọmọ Ènìyàn agbára ayé láti dárí ̀ṣẹ̀ ji ni." Ó fún ẹlẹ́gbà náà , "Mo fún , dìde, gbé àkéte rẹ, o máa lọ ilé!" 25 Ó dìde lọ́gán níwájú wọn, ó gbé ohun ó dùbúlẹ̀ , ó lọ ilé rẹ̀, ó yin Ọlọ́run lógo. 26 Ẹnu ya gbogbo wọn, wọ́n yin Ọlọ́run lógo, ̀wọ́n, wọ́n ń , "Àwa ohun ìyanu lónìí."

Ìpè Lefi

27 Lẹ́hìn èyí, Jesu jáde lọ, ó agbowó òde kan à ń Lefi, ó jókòó ibi ó ti ń gba owó òde, Jesu fún un , "Tẹ̀mi," 28 Lefi fi ohun gbogbo sílẹ̀ ó ń tẹ̀e.

29 Lefi ṣe àsè ńlá kan fún Jesu ilé rẹ̀, ̀pọ̀ àwọn agbowó òde àti àwọn mìíràn ń jẹun pẹ̀wọn. 30 Ṣùgbọ́n àwọn Farisi, àwọn olùkọ́ òfin ó jẹ́ ara wọn fi ̀sùn kan àwọn ọmọ-ẹ̀yìn pe, "Èéṣe ̀yin fi ń jẹun ń pẹ̀àwọn agbowó òde àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀."

31 Jesu dáhùn ó fún wọn , "Ẹni ara rẹ̀ le nílò oníṣègùn, ṣe ẹni ara rẹ̀ . 32 Èmí láti pe àwọn olódodo ṣe àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ìrònúpìwàdà."

A béèrè nípa àwẹ̀ lọ́wọ́ Jesu

33 Wọ́n fún , "Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu a máa gbààwẹ̀, wọn a máa gbàdúrà, bẹ́̀ pẹ̀ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn àwọn Farisi ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ a máa jẹ, wọn a máa mu pẹ̀."

34 Jesu dáhùn ó fún wọn , "Ǹjẹ́ ó ṣe é ṣe àwọn àlejò ọkọ ìyàwó máa gbààwẹ̀ nígbà ọkọ ìyàwó pẹ̀wọn ? 35 Ṣùgbọ́n àkókò ń bọ̀ nígbà a ó gba ọkọ ìyàwó kúrò lọ́dọ̀ wọn, àwọn ọjọ́ wọ̀nyí ni wọn yóò gbààwẹ̀."

36 Ó pa òwe yìí fún wọn , "ẹni ya aṣọ tuntun ó rán mọ́, èyí ti gbó. ó ba ṣe èyí, yóò ba aṣọ tuntun jẹ́, èyí ó tuntun náà yóò dọ́gba pẹ̀èyí ó ti gbó. 37 Àti , ẹni ó ọtí wáìnì tuntun sínú ògbólógbòó ìgò-awọ, ó ṣe èyí, wáìnì tuntun yóò fa awọ náà ya, wáìnì náà yóò dànù, awọ náà a bàjẹ́. 38 Nítorí náà, ó tọ́ á da wáìnì tuntun sínú awọ tuntun. 39 ẹni yóò fẹ́ láti mu wáìnì tuntun lẹ́yìn ó ti mu ògbólógbòó tán, nítorí yóò , Èyí ó jẹ́ ògbólógbòó dára .’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-