Publicidade

Lucas 6

Olúwa Ọjọ́ Ìsinmi

1 ọjọ́ ìsinmi kejì, Jesu ń kọjá láàrín oko ọkà; àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń ya ìpẹ́ ọkà, wọ́n ń jẹ ́. 2 Àwọn kan nínú àwọn Farisi fún wọn , "Ki lo de ̀yin fi ń ṣe èyí yẹ láti ṣe ọjọ́ ìsinmi?"

3 Jesu wọn lóhùn , "̀yin nípa ohun Dafidi ṣe, nígbà ebi ń pa òun tìkára rẹ̀ àti àwọn ó lọ́dọ̀ rẹ̀; 4 bi ó ti wọ ilé Ọlọ́run lọ, ó àkàrà ìfihàn ó jẹ ́, ó fi fún àwọn ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ pẹ̀; yẹ fún un láti jẹ, ṣe fún àwọn àlùfáà nìkan ṣoṣo?" 5 Ó fún wọn , "Ọmọ Ènìyàn ni Olúwa Ọjọ́ Ìsinmi."

6 ọjọ́ ìsinmi mìíràn, ó wọ inú Sinagọgu lọ, ó ń kọ́ni, ọkùnrin kan ń bẹ níbẹ̀ ọwọ́ ̀tún rẹ̀ rọ. 7 Àwọn akọ̀àti àwọn Farisi ń ṣọ́ , bóyá yóò un láradá ọjọ́ ìsinmi; wọn ̀láti fi ̀sùn kàn án. 8 Ṣùgbọ́n ó mọ èrò inú wọn, ó fún ọkùnrin náà ọwọ́ rẹ̀ rọ , "Dìde, o dúró láàrín." Ó dìde dúró.

9 Nígbà náà ni Jesu fún wọn , "Èmi bi yín léèrè, Ó ha tọ́ láti máa ṣe rere ni ọjọ́ ìsinmi, tàbí láti máa ṣe búburú? Láti gba ọkàn , tàbí láti pa á run?"

10 Nígbà ó wo gbogbo wọn yíká, ó fún ọkùnrin náà , "Na ọwọ́ rẹ." Ó ṣe bẹ́̀: ọwọ́ rẹ̀ padà bọ̀ sípò gẹ́gẹ́ èkejì. 11 Wọ́n kún fún ìbínú gbígbóná; wọ́n ara wọn ohun àwọn ìbá ṣe Jesu.

Àwọn aposteli méjìlá

12 Ni ̀kan nínú àwọn ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, Jesu lọ orí òkè láti gbàdúrà, ó fi gbogbo òru náà gbàdúrà Ọlọ́run. 13 Nígbà ilẹ̀ mọ́, ó pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀; nínú wọn ni ó yan méjìlá, ó sọ aposteli:

14 Simoni (ẹni a Peteru) àti Anderu arákùnrin rẹ̀,

Jakọbu,

Johanu,

Filipi,

Bartolomeu,

15 Matiu,

Tomasi,

Jakọbu ọmọ Alfeu,

Simoni a ń Sealoti,

16 Judea arákùnrin Jakọbu,

àti Judasi Iskariotu ó di ̀dàlẹ̀.

Ìbùkún àti ègún

17 Ó wọn sọ̀kalẹ̀, ó dúró pẹ̀tẹ́lẹ̀, pẹ̀̀pọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, àti ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn, láti gbogbo Judea, àti Jerusalẹmu, àti agbègbè Tire àti Sidoni, wọ́n láti gbọ́ ̀rọ̀ rẹ̀, àti láti gba ìmúláradá kúrò nínú ààrùn wọn; 18 àti àwọn ara wọn kún fún ̀àìmọ́ ni ó láradá. 19 Gbogbo ìjọ ènìyàn ń fẹ́ láti fọwọ́ kàn án, nítorí àṣẹ ń jáde lára rẹ̀, ó gbogbo wọn láradá.

20 Nígbà ó gbé ojú rẹ̀ sókè àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó :

"Alábùkún fún ni ̀yin òtòṣì,

nítorí tiyín ni ìjọba Ọlọ́run.

21 Alábùkún fún ni ̀yin ebi ń pa

nísinsin yìí; nítorí ó yóò.

Alábùkún fún ni ̀yin ń

sọkún nísinsin yìí: nítorí ̀yin ó rẹ́rìn-ín.

22 Alábùkún fún ni ̀yin, nígbà àwọn ènìyàn kórìíra yín,

wọ́n yín kúrò nínú ẹgbẹ́ wọn, wọ́n gàn yín,

wọ́n ta orúkọ yín ohun búburú,

nítorí Ọmọ Ènìyàn.

23 "jẹ́ inú yín dùn, fún ayọ̀, nítorí púpọ̀ èrè yín ni ̀run. Báyìí ni àwọn baba yín ṣe ṣe àwọn wòlíì.

24 "Ègbé ni fún ̀yin ọlọ́rọ̀

nítorí ti gba ìtùnú yín.

25 Ègbé ni fún ̀yin ó ,

nítorí ebi yóò pa yín,

Ègbé ni fún ̀yin ń rẹ́rìn-ín nísinsin yìí,

nítorí ̀yin ó ṣọ̀fọ̀, ̀yin ó sọkún.

26 Ègbé ni fún yín, nígbà gbogbo ènìyàn ń sọ̀rọ̀ yín rere,

nítorí bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni àwọn baba wọn ṣe àwọn wòlíì èké.

Ìfẹ́ fún àwọn ̀

27 "Ṣùgbọ́n mo fún ̀yin ń gbọ́ mi, fẹ́ àwọn ̀yín, ṣoore fún àwọn ó kórìíra yín. 28 Súre fún àwọn ń fi yín , gbàdúrà fún àwọn ń kẹ́gàn yín. 29 Ẹni ó ́ ̀rẹ̀kẹ́ kan, kejì i pẹ̀; àti ẹni ó gba agbádá rẹ, ṣe a dúró láti gba ̀àwọ̀tẹ́lẹ̀ rẹ pẹ̀. 30 fi fún gbogbo ẹni ó tọrọ lọ́dọ̀ rẹ; lọ́dọ̀ ẹni ó ẹrù, ṣe padà béèrè. 31 Gẹ́gẹ́ ̀yin ti fẹ́ ènìyàn ṣe yín, ̀yin ṣe bẹ́̀ wọn pẹ̀.

32 "Ǹjẹ́ ̀yin fẹ́ àwọn ó fẹ́ yín, ọpẹ́ ni ̀yin ? Àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ pẹ̀ń fẹ́ àwọn ó fẹ́ wọn. 33 ̀yin ṣoore fún àwọn ó ṣoore fún yín, ọpẹ́ kín ni ̀yin ? Àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ pẹ̀ń ṣe bẹ́̀ gẹ́gẹ́. 34 ̀yin fi fún ẹni ̀yin ń retí láti gbà padà, ọpẹ́ kín ni ̀yin ? Àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ pẹ̀ń ẹlẹ́ṣẹ̀, wọn gba ìwọ̀n bẹ́̀ padà. 35 Ṣùgbọ́n ̀yin fẹ́ àwọn ̀yín ṣoore, ̀yin ẹlòmíràn, ̀yin ṣe retí láti nǹkan gbà padà; èrè yín yóò pọ̀, àwọn ọmọ ̀gá-ògo ni a ó máa yín: nítorí ó ṣe rere fún aláìmoore àti fún ẹni búburú. 36 Ǹjẹ́ ̀yin àánú, gẹ́gẹ́ Baba yín ti àánú.

Dídá ni lẹ́jọ́

37 "ṣe ni lẹ́jọ́, a yóò yín lẹ́jọ́: ṣe ni lẹ́bi, a yóò yín lẹ́bi: dáríjì, a ó dáríjì yín. 38 fi fún ni, a ó fi fún yín; òsùwọ̀n dáradára, àkìmọ́lẹ̀, àti àmìpọ̀, àkúnwọ́sílẹ̀, ni a ó wọ́n si àyà yín: nítorí òsùwọ̀n náà ̀yin fi wọ́n, òun ni a ó padà fi wọ́n fún yín."

39 Ó pa òwe kan fún wọn , "Afọ́ha ṣe amọ̀afọ́? Àwọn méjèèjì kọ́ ni yóò ṣubú sínú ihò ? 40 Ẹni a ń kọ́ í ju olùkọ́ rẹ̀ lọ: ṣùgbọ́n olúkúlùkù ẹni a kọ dáradára, yóò dàbí olùkọ́ rẹ̀.

41 "Èétiṣe ìwọ fi ń wo ̀rún igi ń bẹ ojú arákùnrin rẹ, ṣùgbọ́n ìwọ kíyèsi ìtì igi ń bẹ ojú ara rẹ? 42 Tàbí ìwọ ó ti ṣe fún arákùnrin rẹ , Arákùnrin, jẹ́ èmi yọ ̀rún igi ń bẹ lójú rẹ,nígbà ìwọ tìkára rẹ kíyèsi ìtì igi ń bẹ lójú rẹ? Ìwọ àgàbàgebè, kọ́kọ́ yọ ìtí igi jáde kúrò lójú ara rẹ , nígbà náà ni ìwọ ó ríran gbangba láti yọ èérún igi ń bẹ lójú arákùnrin rẹ kúrò.

Igi àti èso rẹ̀

43 "Nítorí igi rere í so èso búburú; bẹ́̀ ni igi búburú í so èso rere. 44 Olúkúlùkù igi ni a ń fi èso rẹ̀ mọ̀ ọn; nítorí lórí ̀gún òṣùṣú, ènìyàn í èso ̀pọ̀tọ́ bẹ́̀ ni lórí ̀gún ̀gàn a í èso àjàrà. 45 Ènìyàn rere láti inú yàrá ìṣúra rere ọkàn rẹ̀ ohun rere jáde ; àti ènìyàn búburú láti inú ìṣúra búburú ọkàn rẹ̀ í ohun búburú jáde : nítorí láti inú ̀kúnrẹ́rẹ́ ọkàn ẹnu ti máa sọ jáde.

Ọlọ́gbọ́n àti òmùgọ̀ ̀mọ̀

46 "Nítorí náà, èéṣe ̀yin ń , Olúwa, Olúwa,̀yin ṣe ohun mo ? 47 Ẹnikẹ́ni ó tọ̀ , ó ń gbọ́ ̀rọ̀ mi, ó ń ṣe é, èmi yóò fi ẹni ó jọ hàn yín. 48 Ó jọ ọkùnrin kan, ó kọ́ ilé, ó wa ilẹ̀ jìn, ó fi ìpìlẹ̀ sọlẹ̀ lórí àpáta, nígbà kíkún omi , ìgbì omi kọlu ilé náà, ín nítorí a fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ lórí àpáta. 49 Ṣùgbọ́n ẹni ó gbọ́, ṣe é, ó dàbí ọkùnrin ó kọ́ ilé orí ilẹ̀ láìní ìpìlẹ̀; nígbà ìgbì omi kọlù ú, lọ́gán, ó ; wíwó ilé náà pọ̀ púpọ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-