Pular para o conteúdo
Publicidade

Lucas 9

12 Nígbà ọjọ́ bẹ̀rẹ̀ rọlẹ̀, àwọn méjìlá , wọ́n fún un , "ìjọ ènìyàn , wọn lọ ìletò àti ìlú yíká, wọn , àti wọn oúnjẹ: nítorí ijù ni àwa níhìn-ín."

13 9.13: 2Ọb 4.42-44. Ṣùgbọ́n ó fún wọn , "fi oúnjẹ fún wọn jẹ!"

Wọ́n fún un , "Àwa ju ìṣù àkàrà márùn-ún lọ, pẹ̀ẹja méjì: ṣe àwa lọ ra oúnjẹ fún gbogbo àwọn ènìyàn wọ̀nyí." 14 Nítorí àwọn ọkùnrin náà ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ènìyàn.

Ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "wọ́n wọn jókòó lẹ́gbẹ̀̀gbẹ́, àràádọ́ta." 15 Wọ́n ṣe bẹ́̀, wọ́n gbogbo wọn jókòó. 16 9.16: Lk 22.19; 24.30-31; Ap 2.42; 20.11; 27.35.Nígbà náà ni ó ìṣù àkàrà márùn-ún, àti ẹja méjì náà, nígbà ó gbé ojú sókè ̀run, ó súre i, ó ú, ó fi fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, wọn gbé e kalẹ̀ níwájú àwọn ènìyàn. 17 Wọ́n jẹ, gbogbo wọn : wọ́n ṣa agbọ̀n méjìlá jọ nínú àjẹkù ó .

Veja também