Publicidade

Marcos 10

Ìkọ̀sílẹ̀

1 Nígbà náà, Jesu kúrò níbẹ̀, ó ẹkùn Judea níhà òkè odò Jordani. Àwọn ènìyàn tún tọ̀ ́ , i ìṣe rẹ̀, ó kọ́ wọn.

2 Àwọn Farisi kan tọ̀ ́ , láti dán an . Wọ́n béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "Ǹjẹ́ ó ha tọ̀fún ènìyàn láti kọ ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀?"

3 Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn , "ni Mose pàṣẹ fún un yín?"

4 Wọ́n dáhùn , "Mose yọ̀ǹda fún wa láti kọ ìwé ìkọ̀sílẹ̀ fún un, a fi sílẹ̀."

5 Ṣùgbọ́n Jesu wọn lóhùn, ó , "Nítorí líle àyà yín ni Mose fi kọ òfin yìí fun un yín. 6 Ṣùgbọ́n láti ìgbà ayé ti ṣẹ̀, Ọlọ́run wọn akọ àti abo. 7 Nítorí ìdí èyí, ọkùnrin yóò fi baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀ yóò fi ara mọ́ aya rẹ̀. 8 Òun àti ìyàwó rẹ̀ yóò di ara kan náà. Nítorí náà, wọn í túnṣe méjì mọ́ ṣe ẹyọ ̀kan ṣoṣo. 9 Nítorí náà ohun ti Ọlọ́run sọ dọ̀kan, ki ẹnikẹ́ni máa ṣe wọ́n."

10 Lẹ́yìn náà, nígbà Jesu nìkan nínú ilé pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, wọ́n tún béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ nípa ohun kan náà. 11 Jesu túbọ̀ ṣe àlàyé fún wọn , "Ẹnikẹ́ni ó kọ aya rẹ̀ sílẹ̀ ó fẹ́ ẹlòmíràn, irú ọkùnrin bẹ́̀ ṣe panṣágà obìnrin ó ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé níyàwó. 12 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́, obìnrin kan kọ ọkọ rẹ̀ sílẹ̀ ó fẹ́ ọkùnrin mìíràn, irú obìnrin bẹ́̀ ṣe panṣágà."

Jesu àti àwọn ọmọdé

13 Lẹ́yìn èyí, àwọn ènìyàn bẹ̀rẹ̀ í gbé àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ tọ Jesu ó súre fún wọn. Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kígbe mọ́ àwọn ń gbé àwọn ọmọdé wọ̀nyí bọ̀ wọn gbọdọ̀ yọ Jesu lẹ́nu rárá. 14 Ṣùgbọ́n nígbà Jesu ohun ó ń ṣẹlẹ̀, inú rẹ̀ dùn àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. Nítorí náà, ó sọ fún wọn , "jẹ́ àwọn ọmọdé kékeré sọ́dọ̀ mi. ṣe wọn lẹ́kun nítorí irú wọn ni ìjọba Ọlọ́run. 15 Lóòótọ́ ni mo fún yín, ẹnikẹ́ni gba ìjọba Ọlọ́run ọmọ kékeré, yóò le è wọ inú rẹ̀." 16 Nígbà náà, Jesu gbé àwọn ọmọ náà ọwọ́ rẹ̀, ó gbé ọwọ́ orí wọn. Ó súre fún wọn.

̀dọ́mọkùnrin ọlọ́rọ̀

17 Jesu ti bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò rẹ, ọkùnrin kan sáré sọ́dọ̀ rẹ̀. Ó kúnlẹ̀, ó béèrè , "Olùkọ́ rere, ni èmi yóò ṣe láti jogún ìyè àìnípẹ̀kun?"

18 Jesu béèrè , arákùnrin, "Èéṣe o fi ń ẹni rere? Ẹni rere kan Ọlọ́run nìkan ni ẹni rere. 19 Ìwọ mọ àwọn òfin : Ìwọ gbọdọ̀ pànìyàn, ìwọ gbọdọ̀ ṣe panṣágà, ìwọ gbọdọ̀ jalè, ìwọ gbọdọ̀ purọ́, ìwọ gbọdọ̀ rẹ́ ọmọnìkejì jẹ, bọ̀wọ̀ fún baba àti ìyá rẹ.’ "

20 Ọkùnrin náà dáhùn , "Olùkọ́, gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni èmi ń ṣe láti ìgbà èwe mi ."

21 Jesu ó tìfẹ́tìfẹ́. Ó fún un , "ó bẹ́̀, ohun kan fún láti ṣe, lọ nísinsin yìí, ta gbogbo nǹkan o , o pín owó náà fún àwọn aláìní ìwọ yóò ìṣúra ̀run, , ó máa tọ̀ lẹ́yìn."

22 Nígbà ọkùnrin yìí gbọ́ èyí, ojú rẹ̀ korò, ó lọ pẹ̀ìbànújẹ́, nítorí ó ọrọ̀ púpọ̀.

23 Jesu ó ọkùnrin náà ti ń lọ. Ó yípadà, ó sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "Àní, ohun ìṣòro ni fún ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọ́run!"

24 ̀rọ̀ yìí ya àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ lẹ́nu. Jesu tún sọ fún wọn , "Ẹyin ọmọ yóò ṣòro fún àwọn ó ìgbẹ́kẹ̀nínú ọrọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọ́run. 25 Ó rọrùn fún ìbákasẹ láti gba ojú abẹ́rẹ́ wọlé fún ọlọ́rọ̀ kan láti wọ ìjọba ̀run."

26 Ẹnu túbọ̀ ya àwọn ọmọ-ẹ̀yìn i. Wọ́n béèrè , "ó bẹ́̀, ta ni nínú ayé ni ó ìgbàlà?"

27 Jesu wọ́n, ó fún wọn , "Ènìyàn èyí ṣe é ṣe fún ṣùgbọ́n í ṣe fún Ọlọ́run, nítorí ohun gbogbo ni ṣíṣe fún Ọlọ́run."

28 Nígbà náà ni Peteru kọjú Jesu, ó , "Àwa ti fi ohun gbogbo sílẹ̀, a ń tọ̀ ́ lẹ́yìn."

29 Jesu dáhùn , "Lóòótọ́ ni mo fún un yín , ẹnikẹ́ni ó fi ohunkóhun sílẹ̀ : ilé, tàbí àwọn arákùnrin, tàbí àwọn arábìnrin, tàbí ìyá, tàbí baba, tàbí àwọn ọmọ tàbí ohun ìní nítorí mi àti nítorí ìyìnrere, 30 a yóò fún padà ọgọọgọ́rùn-ún àwọn ilé, tàbí arákùnrin, tàbí arábìnrin, tàbí ìyá, tàbí ọmọ, tàbí ilẹ̀, àti inúnibíni pẹ̀. Gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò jẹ́ tirẹ̀ ayé yìí àti ayé ń bọ̀ yóò ìyè àìnípẹ̀kun. 31 Ṣùgbọ́n ̀pọ̀ àwọn ó síwájú ni yóò di ẹni ìkẹyìn, àwọn ó kẹ́yìn yóò síwájú."

Jesu tún sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikú ara rẹ̀

32 Nísinsin yìí, wọ́n lójú ̀Jerusalẹmu. Jesu ń lọ níwájú wọn, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ti ń tẹ̀e, ìbẹ̀kún ọkàn wọn. Ó tún àwọn méjìlá apá kan, ó bẹ̀rẹ̀ ṣàlàyé ohun gbogbo a ó ṣe i fún wọn. 33 Ó sọ fún wọn , "Àwa ń gòkè lọ Jerusalẹmu, a ó fi Ọmọ Ènìyàn àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin lọ́wọ́. Wọn ni yóò lẹ́bi ikú. Wọn yóò á ọwọ́ àwọn aláìkọlà. 34 Wọn yóò fi ṣe ẹlẹ́, wọn yóò tutọ́ ara, wọn yóò pẹ̀pàṣán wọn. Wọn yóò pa, ṣùgbọ́n lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta yóò tún jíǹde."

Ìbéèrè Johanu àti Jakọbu

35 Lẹ́yìn èyí, Jakọbu àti Johanu, àwọn ọmọ Sebede sọ́dọ̀ Jesu. Wọ́n a sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́, wọ́n , "Olùkọ́, inú wa yóò dùn ìwọ ṣe ohunkóhun a béèrè fún wa."

36 Jesu béèrè , "ni ̀yin ń fẹ́ èmi ó ṣe fún un yín?"

37 Wọ́n bẹ̀bẹ̀ , "Jẹ́ ̀kan nínú wa jókòó ọwọ́ ̀tún rẹ àti ẹnìkejì ọwọ́ òsì nínú ògo rẹ!"

38 Ṣùgbọ́n Jesu wọn lóhùn , "mọ ohun ̀ ń béèrè! Ṣe mu nínú ago kíkorò èmi ó tàbí a bamitiisi yín pẹ̀irú ì bamitiisi ìjìyà a ó fi bamitiisi mi?"

39 Àwọn méjèèjì dáhùn , "Àwa pẹ̀ṣe bẹ́̀."

Jesu fún wọn , "Lóòótọ́ ni ̀yin ó mu ago ti èmi yóò mu, àti bamitiisi a bamitiisi mi ni a ó fi bamitiisi yín, 40 ṣùgbọ́n láti jókòó ọwọ́ ̀tún mi àti ọwọ́ òsì mi ì ṣe ti èmi láti fi fún ni: ṣe fún àwọn ẹni a ti pèsè rẹ̀ sílẹ̀ fún."

41 Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mẹ́wàá ìyókù gbọ́ ohun Jakọbu àti Johanu béèrè, wọ́n bínú. 42 Nítorí ìdí èyí, Jesu wọ́n sọ́dọ̀, ó fún wọn , "Gẹ́gẹ́ ̀yin ti mọ̀ , àwọn ọba àti àwọn kèfèrí ń lo agbára lórí àwọn ènìyàn. 43 Ṣùgbọ́n láàrín yín ko gbọdọ̀ ri bẹ. Ẹnikẹ́ni ó fẹ́ di olórí nínú yín gbọdọ̀ ṣe ìránṣẹ́. 44 Ẹnikẹ́ni ó fẹ́ di aṣáájú nínú yín gbọdọ̀ ṣe ìránṣẹ́ gbogbo yín. 45 Nítorí, Èmi, Ọmọ Ènìyàn ayé ṣe ìránṣẹ́ fún mi, ṣùgbọ́n láti ṣe ìránṣẹ́ fun àwọn ẹlòmíràn, àti láti fi ̀rẹ̀ ṣe ìràpadà ̀pọ̀ ènìyàn." 46 Wọ́n Jeriko, Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ àti ̀pọ̀ ènìyàn ti fẹ́ kúrò ìlú Jeriko, ọkùnrin afọ́kan, Bartimeu, ọmọ Timeu jókòó lẹ́gbẹ̀́ ̀ó ń ṣagbe.

Bartimeu afọ́gba ìwòsàn

47 Nígbà Bartimeu gbọ́ Jesu ti Nasareti nítòsí, o bẹ̀rẹ̀ kígbe lóhùn rara , "Jesu ọmọ Dafidi, ṣàánú fún mi."

48 Àwọn níbẹ̀ kígbe mọ́ ọn , "Pa ẹnu rẹ mọ́." Ṣùgbọ́n dípò ó pa ẹnu mọ́, ṣe ń kígbe lóhùn rara , "Jesu ọmọ Dafidi ṣàánú fún mi."

49 Nígbà Jesu gbọ́ igbe rẹ̀, ó dẹ́sẹ̀ dúró lójú ̀, ó , "é ó sọ́dọ̀ mi."

Nítorí náà wọ́n pe ọkùnrin afọ́náà, wọ́n , "Tújúká! Dìde lórí ẹsẹ̀ rẹ! Ó ń ́." 50 Lẹ́sẹ̀kan náà, Bartimeu bọ́ agbádá rẹ̀ sọnù, ó sókè, ó sọ́dọ̀ Jesu.

51 Jesu béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "ni ìwọ fẹ́ èmi ó ṣe fún ?"

Afọ́náà dáhùn , "Rabbi, jẹ́ èmi ó ríran."

52 Jesu fún un , "Máa lọ, ìgbàgbọ́ rẹ ti láradá." Lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀, ọkùnrin afọ́náà ríran ó ń tẹ̀Jesu lọ ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-