Pular para o conteúdo
Publicidade

Marcos 10

4 10.4: De 24.1-4. Wọ́n dáhùn , "Mose yọ̀ǹda fún wa láti kọ ìwé ìkọ̀sílẹ̀ fún un, a fi sílẹ̀."

5 Ṣùgbọ́n Jesu wọn lóhùn, ó , "Nítorí líle àyà yín ni Mose fi kọ òfin yìí fun un yín. 6 10.6: Gẹ 1.27; 5.2.Ṣùgbọ́n láti ìgbà ayé ti ṣẹ̀, Ọlọ́run wọn akọ àti abo. 7 10.7-8: Gẹ 2.24.Nítorí ìdí èyí, ọkùnrin yóò fi baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀ yóò fi ara mọ́ aya rẹ̀. 8 Òun àti ìyàwó rẹ̀ yóò di ara kan náà. Nítorí náà, wọn í túnṣe méjì mọ́ ṣe ẹyọ ̀kan ṣoṣo. 9 Nítorí náà ohun ti Ọlọ́run sọ dọ̀kan, ki ẹnikẹ́ni máa ṣe wọ́n."

Veja também