Publicidade

Marcos 13

Àwọn àmì òpin ayé

1 Jesu ti ń jáde láti inú tẹmpili ọjọ́ náà, ̀kan nínú ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ fún un , "Olùkọ́, wo ilé ńlá ó dára wọ̀nyí. wo òkúta a ṣe lọ́ṣọ̀́ lára àwọn ògiri ilé náà."

2 Jesu dáhùn , "Ìwọ ilé ńlá wọ̀nyí? yóò òkúta kan a ó fi sílẹ̀ lórí èkejì a yóò lulẹ̀."

3 Jesu si ti jókòó lórí òkè olifi ó kọjú tẹmpili, Peteru, Jakọbu, Johanu àti Anderu pẹ̀rẹ̀ níbẹ̀, wọ́n bi í léèrè ni ìkọ̀kọ̀ , 4 "Sọ fún wa, nígbà wo ni nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹlẹ̀ tẹmpili náà? ni yóò jẹ́ àmì nígbà gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹ?"

5 Jesu kìlọ̀ fún wọn , "ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni tàn yín. 6 Nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ yóò orúkọ mi, wọn yóò , Èmi ni Kristi,wọn yóò tan ̀pọ̀ ènìyàn jẹ. 7 Nígbà ̀yin ń gbọ́ ìró ogun àti ìdágìrì ogun, ̀yin ṣe jáyà, nítorí irú nǹkan wọ̀nyí le ṣe ó ṣẹlẹ̀, ṣùgbọ́n òpin náà í ṣe ìgbà yìí. 8 Orílẹ̀-èdè yóò dìde orílẹ̀-èdè, àti ìjọba ìjọba ilẹ̀ yóò máa ibi púpọ̀. Ìyàn yóò níbi gbogbo. Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni ìbẹ̀rẹ̀ ìpọ́njú ń bọ̀ níwájú.

9 "Ṣùgbọ́n nígbà àwọn nǹkan wọ̀nyí bẹ̀rẹ̀ i ṣẹlẹ̀, kíyèsára! Nítorí ̀yin yóò nínú ewu. Wọn yóò yín lọ ilé ẹjọ́ gbogbo. Wọn yóò fi ìyà jẹ yín nínú Sinagọgu wọn. Àwọn ènìyàn yóò fẹ̀sùn kàn yín níwájú àwọn baálẹ̀ àti níwájú àwọn ọba nítorí orúkọ mi, fún ̀fún wọn. 10 Nítorí gbọdọ̀ kọ́kọ́ wàásù ìyìnrere náà fún gbogbo orílẹ̀-èdè òpin . 11 Ṣùgbọ́n nígbà wọ́n ń yín lọ, wọ́n ń fi yín wọn lọ́wọ́, ṣe ṣàníyàn ṣáájú ohun ó sọ. Ṣùgbọ́n ohun fi fún yín wákàtí náà, òun ni ̀yin ó . Nítorí í ṣe ̀yin ni ó ń , ṣe ̀Mímọ́.

12 "Arákùnrin yóò máa fi ̀sùn kan arákùnrin rẹ̀, yóò yọrí ikú. Baba yóò máa ṣe ikú pa ọmọ rẹ̀. Àwọn ọmọ yóò máa dìtẹ̀ òbí wọn. Àní, àwọn ọmọ pẹ̀yóò máa ṣe ikú pa òbí wọn. 13 Àwọn ènìyàn yóò kórìíra yín nítorí jẹ́ tèmi. Ṣùgbọ́n ẹni fi ara da ìyà títí òpin kọ̀ sílẹ̀ òun ni yóò ìgbàlà.

14 "Ṣùgbọ́n nígbà ̀yin ìríra ìsọdahoro, ó dúró níbí yẹ (ẹnikẹ́ni ó á ó e), nígbà náà ni àwọn ń bẹ ni Judea sálọ orí òkè. 15 ẹni ti ń bẹ lórí ilé ṣe sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ilé, bẹ́̀ ni ó ṣe wọ inú rẹ̀, láti ohunkóhun jáde nínú ilé rẹ̀. 16 ẹni ó lóko ṣe padà sẹ́yìn láti aṣọ rẹ̀. 17 Ègbé fún àwọn ó lóyún, àti fún obìnrin ń fún ́mọ lọ́ọjọ́ wọ̀nyí. 18 máa gbàdúrà èyí ṣẹlẹ̀ àkókò òtútù. 19 Nítorí ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì yóò jẹ́ àkókò ìpọ́njú, irú èyí ì ṣẹlẹ̀ láti ìbẹ̀rẹ̀ ̀Ọlọ́run. Irú rẹ̀ ni ṣẹlẹ̀ mọ́.

20 "Àfi Olúwa àkókò ìjìyà náà kúrú, ẹyọ ̀kan ayé yóò . Ṣùgbọ́n nítorí àwọn Ọlọ́run yàn, ni yóò ṣe dín àwọn ọjọ́ náà . 21 Nígbà náà, ẹnikẹ́ni sọ fún un yín , ó, Kristi wa níbi yìí!tàbí, sọ fún un yín , ó, ó lọ́hùn ún !ṣe gbà wọ́n gbọ́. 22 Nítorí àwọn èké Kristi àti àwọn wòlíì èké ni yóò , wọn yóò fi iṣẹ́ ìyanu yóò tan ènìyàn jẹ hàn. ó ṣe é ṣe, wọn yóò tan àwọn àyànfẹ́ pàápàá jẹ. 23 Nítorí náà, ṣọ́ra. Mo ti kìlọ̀ fún un yín ṣáájú !

24 "Ṣùgbọ́n ni ọjọ́ wọ̀nyí lẹ́yìn ìpọ́njú mo sọ yìí,

" oòrùn yóò ṣókùnkùn,

òṣùpá tan ìmọ́lẹ̀ rẹ̀.

25 Àwọn ìràwọ̀ pẹ̀yóò lulẹ̀ láti ojú ̀run,

àti agbára ń bẹ ̀run ni a ó tìtì.

26 "Nígbà náà ni gbogbo ayé yóò i èmi Ọmọ Ènìyàn yóò máa bọ̀ láti inú àwọsánmọ̀ pẹ̀agbára àti ògo ńlá. 27 Nígbà náà ni yóò rán àwọn angẹli rẹ̀ láti àwọn àyànfẹ́ gbogbo ayé jọ láti orígun mẹ́rẹ̀̀rin ayé láti ìkangun ayé títí ìkangun ̀run.

28 "Nísinsin yìí, kọ́ òwe lára igi ̀pọ̀tọ́, nígbà ̀ka rẹ ń yọ tuntun, ó ń ewé, èyí fihàn àkókò ̀rùn ti . 29 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́, nígbà ba ri àwọn ohun wọ̀nyí ti n ṣẹlẹ̀, mọ̀ ó súnmọ́ etílé tán, bi ìgbà ó lẹ́yìn ìlẹ̀kùn. 30 Lóòótọ́ ni mo fún un yín, ìran yìí yóò rékọjá títí a ó fi gbogbo nǹkan wọ̀nyí ṣẹ. 31 ̀run àti ayé yóò kọjá lọ, ṣùgbọ́n àwọn ̀rọ̀ mi dúró dájú títí ayé àìnípẹ̀kun.

Ọjọ́ àti wákàtí a mọ̀

32 "Ṣùgbọ́n ẹni ó mọ ọjọ́ tàbí wákàtí nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹlẹ̀. Àwọn angẹli ̀run pàápàá mọ̀. Àní, èmi pẹ̀mọ̀ ́n, ṣe baba nìkan. 33 máa ṣọ́ra, dúró wámú, máa gbàdúrà, nítorí ̀yin mọ ìgbà àkókò yóò . 34 Ó ọkùnrin kan ó lọ ìrìnàjò ó jìnnà rere, ẹni ó fi ilé rẹ̀ sílẹ̀, ó fi àṣẹ fún àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀, àti iṣẹ́ ẹnìkọ̀̀kan yóò ṣe, ó fi àṣẹ fún ẹni dúró lẹ́nu-ọ̀láti máa ṣọ́.

35 "Bẹ́̀ gẹ́gẹ́, ̀yin pẹ̀láti máa fi ìrètí ṣọ́, nítorí mọ àkókò baálé ilé yóò . Bóyá ìrọ̀lẹ́ ni o, tàbí ̀gànjọ́ òru, tàbí nígbà àkùkọ máa ń kọ, tàbí òwúrọ̀. 36 Àti nígbà ó lójijì, ṣe yín lójú oorun. 37 Ohun mo fún un yín, mo fun gbogbo ènìyàn: máa ṣọ́!’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-