Pular para o conteúdo
Publicidade

Marcos 3

1 3.1-6: Mt 12.9-14; Lk 6.6-11. Nígbà Jesu Sinagọgu. kíyèsi i ọkùnrin kan níbẹ̀, ọwọ́ rẹ̀ kan rọ. 2 3.2: Lk 11.54.Àwọn kan nínú wọn ń wa ̀láti fi ̀sùn kan Jesu. Nítorí náà, wọ́n ń ṣọ́ yóò un láradá ọjọ́ ìsinmi. 3 Jesu fún ọkùnrin ọwọ́ rẹ̀ rọ náà , "Dìde dúró iwájú ìjọ ènìyàn."

4 Nígbà náà ni Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn , "Ǹjẹ́ ó òfin mu ọjọ́ ìsinmi bóyá láti ṣe rere, tàbí láti ṣe búburú! Láti gbà ̀, tàbí pa á run?" Ṣùgbọ́n wọ́n dákẹ́ láìfèsì.

5 Nígbà ó wo gbogbo wọn yíká pẹ̀ìbínú, ọkàn rẹ̀ bàjẹ́ nítorí líle àyà wọn, ó sọ fún ọkùnrin náà , "Na ọwọ́ rẹ jáde." Ó án jáde, ọwọ́ náà bọ̀ sípò padà pátápátá.

Veja também