Pular para o conteúdo
Publicidade

Marcos 6

Wòlíì ọlá

1 6.1-6: Mt 13.53-58; Lk 4.16-30. Jesu fi ibẹ̀ sílẹ̀ lọ ìlú rẹ̀ pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. 2 6.2: Mk 1.21; Mt 7.28.Nígbà ó di ọjọ́ ìsinmi, ó lọ Sinagọgu láti kọ́ àwọn ènìyàn, ẹnu ya àwọn ènìyàn púpọ̀ ó gbọ́.

Wọ́n , "Níbo ni ọkùnrin yìí gbé ti nǹkan wọ̀nyí? Irú ọgbọ́n ni èyí a fi fún un, irú iṣẹ́ ìyanu báyìí ń ti ọwọ́ rẹ̀ ṣe? 3 6.3: Mt 11.6.Gbẹ́nàgbẹ́náà kọ́ yìí? Ọmọ Maria àti arákùnrin Jakọbu àti Josẹfu, Judasi àti Simoni? Àwọn arábìnrin rẹ̀ gbogbo ha kọ́ ni ó ń wa gbé níhìn-ín yìí?" Wọ́n kọsẹ̀ lára rẹ̀.

4 Nígbà náà, Jesu fún wọn , "A máa ń bu ọlá fún wòlíì níbi gbogbo àfi ìlú ara rẹ̀ àti láàrín àwọn ìdílé àti àwọn ẹbí òun pàápàá." 5 6.5: Mk 5.23; 7.32; 8.23.Nítorí àìgbàgbọ́ wọn, òun ṣe iṣẹ́ ìyanu ńlá láàrín wọn, àfi àwọn aláìsàn díẹ̀ ó gbé ọwọ́ lórí, wọ́n ìwòsàn.

Jesu rán ọmọ-ẹ̀yìn méjìlá jáde

6 6.6: Mt 9.35. Ẹnu si á nítorí àìgbàgbọ́ wọn. Lẹ́yìn náà, Jesu lọ àárín àwọn ìletò kéékèèké, ó ń kọ́ wọn. 7 6.7-11: Mt 10.1,5,7-11; Lk 9.1-5.6.7: Lk 10.1.Ó pe àwọn méjìlá náà sọ́dọ̀ rẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ rán wọn lọ méjì méjì, Ó fi àṣẹ fún wọn lórí ̀àìmọ́.

8 O sọ fún wọn , wọn gbọdọ̀ ohunkóhun lọ́wọ́, àfi ̀ìtìlẹ̀ wọn. Wọn gbọdọ̀ oúnjẹ, àpò ìgbànú, tàbí owó lọ́wọ́. 9 Wọn tilẹ̀ gbọdọ̀ ìpààrọ̀ bàtà tàbí aṣọ lọ́wọ́. 10 Jesu , "dúró ilé kan ìletò kan. ṣe sípò padà láti ilé ilé, nígbà ìlú náà. 11 6.11: Mt 10.14.Ẹnikẹ́ni gbà yín, gbọ́rọ̀ yín, nígbà ̀yin jáde kúrò níbẹ̀, gbọn eruku ẹsẹ̀ yín síbẹ̀ fún ̀fún wọn."

12 6.12-13: Mt 11.1; Lk 9.6. Wọ́n jáde lọ láti wàásù ìrònúpìwàdà fún àwọn ènìyàn. 13 6.13: Jk 5.14.Wọ́n ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ̀àìmọ́ jáde. Wọ́n ń fi òróró kun orí àwọn ara wọn , wọ́n wọn láradá.

A bẹ́ Johanu onítẹ̀bọmi lórí

14 6.14-16: Mt 14.1-2; Lk 9.7-9; 9.19; Mt 21.11. Láìpẹ́, ọba Herodu gbọ́ nípa Jesu, nítorí níbi gbogbo ni a ti ń sọ̀rọ̀ iṣẹ́ ìyanu rẹ̀. Ọba náà , "Johanu Onítẹ̀bọmi jíǹde kúrò nínú òkú, nítorí náà ni iṣẹ́ ìyanu ṣe ń ṣe láti ọwọ́ rẹ."

15 Àwọn mìíràn , "Elijah ."

Àwọn mìíràn , "Wòlíì ̀kan lára àwọn àtijọ́ ti tún padà sáyé."

16 Ṣùgbọ́n nígbà Herodu gbọ́ èyí, ó "Johanu mo bẹ́ lórí ni ó ti jíǹde kúrò nínú òkú."

17 6.17-18: Mt 14.3-4; Lk 3.19-20. Herodu fúnra rẹ̀ ti ránṣẹ́ Johanu, tìkára rẹ̀ sínú túbú nítorí Herodia aya Filipi arákùnrin rẹ̀ nítorí ó fi ṣe aya. 18 Johanu ti fún Herodu , "tọ́ láti fi ìyàwó arákùnrin rẹ ṣe aya." 19 6.19-29: Mt 14.5-12.Nítorí náà ni Herodia ṣe sínú, òun fẹ́ pa á, ṣùgbọ́n le ṣe é. 20 6.20: Mt 21.26.Nítorí Herodu bẹ̀Johanu, ó mọ̀ ́n ni olóòtítọ́ ènìyàn àti ẹni mímọ́, ó ń tọ́rẹ̀. Nígbà Herodu ba gbọ́rọ̀ Johanu, ó máa ń dààmú síbẹ̀, ó fi ayọ̀ gbọ́rọ̀ rẹ̀.

21 Níkẹyìn Herodia ààyè. Àkókò yìí ni ọjọ́ ìbí Herodu, òun pèsè àsè ààfin ọba fún àwọn olùrànlọ́wọ́ rẹ̀: àwọn balógun àti àwọn ènìyàn pàtàkì Galili. 22 Nígbà náà, ni ọmọbìnrin Herodia wọlé láti . Inú Herodu àti àwọn àlejò rẹ̀ dùn bẹ́̀.

Ọba sọ fún ọmọbìnrin náà , "Béèrè ohunkóhun ìwọ fẹ́ lọ́wọ́ mi, èmi ó fi fún ." 23 6.23: Es 5.3,6.Ó búra fún un , "Ohunkóhun ìwọ fẹ́, ìbá à ṣe ìdajì ìjọba mi ni, èmi yóò fi fún ."

24 Ó jáde lọ sọ fún ìyá rẹ̀ , "ń béèrè?"

Ó dáhùn , "Orí Johanu Onítẹ̀bọmi."

25 Ọmọbìnrin yìí sáré padà sọ́dọ̀ Herodu ọba. Ó fún un , "Mo ń fẹ́ orí Johanu Onítẹ̀bọmi nísinsin yìí nínú àwopọ̀kọ́."

26 Inú ọba bàjẹ́ gidigidi, ṣùgbọ́n nítorí àwọn ìbúra rẹ, àti nítorí àwọn ó a jókòó pọ̀, fẹ́ kọ̀ fún un. 27 Nítorí èyí, ọba rán ̀ṣọ́ kan, ó fi àṣẹ fún un , ó gbé orí Johanu . Ọkùnrin náà lọ, ó bẹ́ Johanu lórí nínú túbú. 28 Ó gbé orí Johanu wa nínú àwopọ̀kọ́. Ó gbé e fún ọmọbìnrin náà. Òun gbé e tọ ìyá rẹ̀ lọ. 29 Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu gbọ́, wọ́n gbé òkú rẹ̀, wọ́n lọ tẹ́ sínú ibojì.

Jesu bọ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ènìyàn

30 6.30-31: Lk 9.10; Mk 3.20. Àwọn aposteli ara wọn jọ ̀dọ̀ Jesu, wọ́n ròyìn ohun gbogbo wọ́n ti ṣe àti ohun gbogbo wọ́n ti kọ́ni. 31 Nígbà Jesu i ̀pọ̀ ènìyàn ń lọ wọ́n ń bọ̀ bẹ́̀ ààyè fún wọn láti jẹun, ó fún wọn , "jẹ́ a kúrò láàrín ̀pọ̀ ènìyàn wọ̀nyí fún ìgbà díẹ̀, a sinmi."

32 6.32-44: Mt 14.13-21; Lk 9.11-17; Jh 6.5-13; Mk 8.1-10; Mt 15.32-39. Nítorí náà, wọ́n wọ ọkọ̀ ojú omi kúrò níbẹ̀ lọ ibi ó parọ́rọ́. 33 Ṣùgbọ́n ̀pọ̀ ènìyàn ni o wọn nígbà wọ́n ń lọ. Àwọn wọ̀nyí tún láti ìlú ńlá gbogbo wọn sáré gba etí Òkun, wọ́n ṣáájú wọn gúnlẹ̀ èbúté. 34 6.34: Mt 9.36.Jesu ti ń sọ̀kalẹ̀ láti inú ọkọ̀ náà, ó ̀pọ̀ ènìyàn i àtẹ̀yìnwá, wọ́n ti ń dúró e. Ó káàánú fún wọn, nítorí wọ́n dàbí àgùntàn olùtọ́. Ó kọ́ wọn ni ̀pọ̀ nǹkan ó yẹ wọ́n mọ̀.

35 Nígbà ọjọ́ ti lọ tán, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ̀ ́ , wọ́n fún un , ibi aṣálẹ̀ ni ìbí yìí, ọjọ́ lọ tán. 36 "Rán àwọn ènìyàn wọ̀nyí láti lọ àwọn abúlé àti ìlú láti ra oúnjẹ fún ara wọn."

37 6.37: 2Ọb 4.42-44. Ṣùgbọ́n Jesu sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "fún wọn oúnjẹ."

Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn fún , "Èyí yóò wa owó iṣẹ́ ̀oṣù mẹ́jọ, ṣe a lọ fi èyí ra àkàrà fún àwọn ̀pọ̀ ènìyàn yìí láti jẹ."

38 Jesu tún béèrè , "Ìṣù àkàrà mélòó ni ̀yin ni lọ́wọ́? lọ ó."

Wọ́n padà jíṣẹ́ , "Ìṣù àkàrà márùn-ún àti ẹja méjì."

39 Nígbà náà ni Jesu sọ fún ̀pọ̀ ènìyàn náà a wọn jókòó lẹ́gbẹ̀̀gbẹ́ lórí koríko. 40 Lẹ́sẹ̀kan náà, wọ́n bẹ̀rẹ̀ í jókòó, àádọ́ta tàbí ọgọọgọ́rùn-ún. 41 6.41: Mk 14.22; Lk 24.30-31.Nígbà ó ìṣù àkàrà márùn-ún àti ẹja méjì náà, ó gbé ojú rẹ̀ sókè ̀run. Ó dúpẹ́ fún oúnjẹ náà, ó wọ́n wẹ́wẹ́, ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ láti gbé e kalẹ̀ síwájú àwọn ènìyàn náà àti àwọn ẹja méjì náà ni ó pín fún gbogbo wọn. 42 Gbogbo wọn jẹ àjẹyó. 43 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn agbọ̀n méjìlá ó kún fún àjẹkù àkàrà àti ti ẹja pẹ̀. 44 Àwọn ó jẹ́ àkàrà náà ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ọkùnrin.

Jesu rìn lórí omi

45 6.45-52: Mt 14.22-33; Jh 6.15-21. Lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ lẹ́yìn èyí, Jesu pàṣẹ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ láti padà sínú ọkọ̀ wọn ṣáájú rékọjá Betisaida. Níbẹ̀ ni òun yóò ti pẹ̀wọn láìpẹ́. Nítorí òun fúnra a rẹ̀ yóò dúró sẹ́yìn láti i àwọn ènìyàn túká lọ ilé wọn. 46 Lẹ́yìn náà, ó lọ sórí òkè láti lọ gbàdúrà.

47 Nígbà ó di alẹ́, ọkọ̀ láàrín Òkun, òun nìkan lórí ilẹ̀. 48 6.48: Mk 13.35.Ó i àwọn ọmọ-ẹ̀yìn nínú wàhálà púpọ̀ wíwa ọkọ̀ náà nítorí ti ìjì líle ṣe ọwọ́ òdì wọn, nígbà ó ìwọ̀n ìṣọ́ kẹrin òru, ó tọ̀ wọ́n , ó ń rìn lórí omi Òkun, òun fẹ́ wọn kọjá, 49 ṣùgbọ́n nígbà wọ́n i ó ń rìn, wọ́n iwin ni. Wọ́n kígbe sókè lóhùn rara, 50 6.50: Mt 9.2.nítorí gbogbo wọn ni ó i, ̀wọ́n.

Ṣùgbọ́n òun sọ̀rọ̀ wọn lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ , "ọkàn le! Èmi ni. bẹ̀." 51 Nígbà náà ni ó gòkè sínú ọkọ̀ pẹ̀wọn, ìjì líle náà dáwọ́ dúró. ̀wọ́n rékọjá gidigidi, ẹnu wọ́n. 52 6.52: Mk 8.17.Wọn ni òye iṣẹ́ ìyanu ti ìṣù àkàrà, nítorí ti ọkàn wọn yigbì.

53 6.53-56: Mt 14.34-36. Lẹ́yìn wọ́n la Òkun náà kọjá, wọ́n gúnlẹ̀ Genesareti. Wọ́n so ọkọ̀ èbúté. 54 Wọ́n jáde kúrò nínú ọkọ̀. Àwọn ènìyàn níbẹ̀ Jesu, wọ́n a mọ̀ ́n. 55 Wéré, wọ́n ròyìn dídé rẹ̀, gbogbo àwọn ènìyàn sáré gbé gbogbo àwọn aláìsàn lórí àkéte wọn pàdé rẹ̀. 56 6.56: Mk 3.10; Mt 9.20.ibi gbogbo ó , yálà abúlé, ìlú ńlá tàbí àrọ́ko, ń ṣe ni wọ́n ń àwọn aláìsàn pàdé rẹ̀ àárín ọjà. Wọ́n ń bẹ̀ ́ ó jẹ́ wọn fi ọwọ́ kan etí aṣọ rẹ̀, gbogbo àwọn wọ́n fi ọwọ́ kàn án ni a láradá.

Veja também