Pular para o conteúdo
Publicidade

Marku 7

20 7.20-23: Ro 1.28-31; Ga 5.19-21. Nígbà náà, ó fi kún un , "Èyí ti ó ti ọkàn ènìyàn jáde ni ń sọ ni di aláìmọ́. 21 Nítorí láti inú ọkàn ènìyàn ni àwọn èrò búburú wọ̀nyí ti ń jáde : àgbèrè, olè, ìpànìyàn, panṣágà, 22 7.22: Mt 6.23; 20.15.̀kánjúwà, odì yíyàn, ìtànjẹ, ìmọ-tara-ẹni, ìlara, ̀rọ̀ ̀yìn, ìgbéraga, òmùgọ̀. 23 Gbogbo àwọn nǹkan búburú wọ̀nyí ń inú , àwọn ń sọ yín di aláìmọ́."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também