Publicidade

Mateus 16

Bíbéèrè Fún Àmì

1 Àwọn Farisi àti àwọn Sadusi láti dán Jesu . Wọ́n ó fi àmì ńlá kan hàn àwọn ojú ̀run.

2 Ó wọn lóhùn , "Nígbà ó di àṣálẹ́, ó sọ , Ìbá dára ojú ̀run pọ́n. 3 òwúrọ̀, ̀yin yóò ọjọ́ yóò dára lónìí, nítorí ti ojú ̀run pọ́n, ó ṣú dẹ̀dẹ̀,’ ̀yin àgàbàgebè, ̀yin le sọ àmì ojú ̀run, ṣùgbọ́n ̀yin le mọ àmì àwọn àkókò wọ̀nyí. 4 Ìran búburú aláìgbàgbọ́ yìí ń béèrè àmì àjèjì mélòó kàn ni ojú sánmọ̀, ṣùgbọ́n a yóò fún ẹnìkankan àmì ṣe àmì Jona." Nígbà náà ni Jesu fi wọ́n sílẹ̀, ó tirẹ̀ lọ.

Ìwúkàrà Farisi àti Sadusi

5 Nígbà wọ́n apá kejì adágún, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ṣàkíyèsí wọ́n ti gbàgbé láti àkàrà kankan lọ́wọ́. 6 Jesu kìlọ̀ fún wọn , "kíyèsára, ṣọ́ra, ti ìwúkàrà àwọn Farisi àti àwọn Sadusi."

7 Wọ́n ń sọ eléyìí ni àárín ara wọn , "Nítorí àwa àkàrà lọ́wọ́ ni."

8 Nígbà ó gbọ́ ohun ti wọ́n ń sọ, Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn , "̀yin onígbàgbọ́ kékeré, èéṣe ̀yin ń dààmú ara yín ̀yin oúnjẹ lọ́wọ́? 9 Tàbí ̀rọ̀ yín di ìsinsin yìí? ̀yin rántí mo bọ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ènìyàn pẹ̀ìṣù àkàrà márùn-ún àti iye agbọ̀n kójọ àjẹkù? 10 tún rántí ìṣù méje mo fi bọ́ ẹgbàajì (4,000) ènìyàn àti iye agbọ̀n ̀yín kójọ? 11 Èéha ṣe fi yín èmi sọ̀rọ̀ nípa ti àkàrà? Lẹ́̀kan i, mo fún yín, ṣọ́ra fún ìwúkàrà àwọn Farisi àti ti Sadusi." 12 Nígbà náà ni ó ṣẹ̀ṣẹ̀ wáyé wọn , í ṣe nípa ti ìwúkàrà ó sọ wọ́n kíyèsára, ṣe ̀kọ́ àwọn Farisi àti Sadusi.

Peteru jẹ́wọ́ Kristi

13 Nígbà Jesu Kesarea-Filipi, ó bi àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "Ta ni àwọn ènìyàn ń fi Ọmọ Ènìyàn ?"

14 Wọ́n a lóhùn , "Àwọn kan ni Johanu onítẹ̀bọmi ni, àwọn mìíràn , Elijah ni, àwọn mìíràn , Jeremiah ni, tàbí ̀kan nínú àwọn wòlíì."

15 "Ṣùgbọ́n ẹyin ń kọ?" Ó bi í léèrè , "Ta ni ̀yin ń fi mi ?"

16 Simoni Peteru dáhùn , "Ìwọ ni Kristi náà, Ọmọ Ọlọ́run alààyè."

17 Jesu fún un , "Alábùkún fún ni ìwọ Simoni ọmọ Jona, nítorí ẹran-ara àti ̀jẹ̀ kọ́ fi èyí hàn ṣe Baba mi ó ń bẹ ̀run. 18 Èmi fún , ìwọ ni Peteru àti orí àpáta yìí ni èmi yóò kọ́ ìjọ mi , àti ẹnu-ọ̀ipò òkú yóò borí rẹ̀. 19 Èmi yóò fún àwọn kọ́kọ́rọ́ ìjọba ̀run; ohun ìwọ ayé, òun ni a ó ̀run. Ohunkóhun ìwọ ayé yìí, a ó ̀run." 20 Nígbà náà ó kìlọ̀ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wọn gbọdọ̀ sọ fún ẹnikẹ́ni Òun ni Kristi náà.

Jesu sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikú ara rẹ̀

21 Láti ìgbà yìí lọ, Jesu bẹ̀rẹ̀ ṣàlàyé fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kedere nípa lílọ Jerusalẹmu láti jẹ ̀pọ̀ ìyà lọ́wọ́ àwọn àgbàgbà, àwọn olórí àlùfáà àti àwọn akọ̀, a pa òun, àti ọjọ́ kẹta, ó jíǹde.

22 Peteru Jesu ̀gbẹ́ kan, ó bẹ̀rẹ̀ í a , "a i Olúwa! Èyí yóò ṣẹlẹ̀ !"

23 Jesu pa ojú , ó fún Peteru , "Kúrò lẹ́yìn mi, Satani! Ohun ìkọ̀sẹ̀ ni ìwọ jẹ́ fún mi; ìwọ ro ohun i ṣe ti Ọlọ́run, ṣe èyí ti ṣe ti ènìyàn."

24 Nígbà náà ni Jesu fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "ẹnikẹ́ni fẹ́ tọ̀ lẹ́yìn, ó sẹ́ ara rẹ̀, ó gbé àgbélébùú rẹ̀, ó máa tọ̀ lẹ́yìn. 25 Nítorí ẹnikẹ́ni ó fẹ́ gba ̀rẹ̀ , yóò sọ ̀rẹ̀ ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ó sọ ̀rẹ̀ nítorí mi, yóò i. 26 Èrè ni ó jẹ́ fún ènìyàn ó jèrè gbogbo ayé yìí, ó sọ ̀rẹ̀ ? Tàbí ni ènìyàn yóò fi dípò ̀rẹ̀? 27 Nítorí Ọmọ Ènìyàn yóò nínú ògo baba rẹ pẹ̀àwọn angẹli rẹ̀, nígbà náà ni yóò san án fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ iṣẹ́ rẹ̀.

28 "Lóòótọ́ ni mo fún yín. Ẹlòmíràn nínú àwọn ó níhìn-ín yìí, yóò ri ikú títí wọn ó fi Ọmọ Ènìyàn yóò máa bọ̀ ìjọba rẹ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-