Jesu sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikú ara rẹ̀
21 16.21-28: Mk 8.31–9.1; Lk 9.22-27. 16.21: Mt 17.22-23; 20.17-19; Lk 17.25; Mt 17.12; 26.2. Láti ìgbà yìí lọ, Jesu bẹ̀rẹ̀ sí ṣàlàyé fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kedere nípa lílọ sí Jerusalẹmu láti jẹ ọ̀pọ̀ ìyà lọ́wọ́ àwọn àgbàgbà, àwọn olórí àlùfáà àti àwọn akọ̀wé, kí a sì pa òun, àti ní ọjọ́ kẹta, kí ó sì jíǹde.