Publicidade

Mateus 19

Ìkọ̀sílẹ̀

1 Lẹ́yìn Jesu ti parí ̀rọ̀ yìí, ó kúrò Galili. Ó yípo padà Judea, ó gba ìhà kejì odò Jordani. 2 ̀pọ̀ ènìyàn ń tọ̀ ́ lẹ́yìn, ó wọn láradá níbẹ̀.

3 Àwọn Farisi sọ́dọ̀ rẹ̀ láti dán an . Wọ́n bi í , "Ǹjẹ́ ó tọ̀fún ọkùnrin láti kọ ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀ nítorí ohunkóhun?"

4 Ó dáhùn ó fún wọn , "Ẹyin ti á ẹni ó wọn ìgbà àtètèkọ́ṣe, Ọlọ́run wọn ni ti akọ ti abo. 5 Ó fún un , Nítorí ìdí èyí ọkùnrin yóò fi baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀, òun yóò dàpọ̀ mọ́ aya rẹ̀, àwọn méjèèjì yóò di ara kan. 6 Wọn í túnṣe méjì mọ́, ṣùgbọ́n ara kan. Nítorí náà, ohun Ọlọ́run ti so ṣọ̀kan, ẹnikẹ́ni ṣe wọ́n."

7 Wọ́n bi í : "ni ìdí Mose fi pàṣẹ , ọkùnrin kan kọ ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀ nípa fífún un ìwé ìkọ̀sílẹ̀?"

8 Jesu dáhùn , "Nítorí líle àyà yín ni Mose ṣe gbà fún yín láti máa kọ aya yín sílẹ̀. Ṣùgbọ́n láti ìgbà àtètèkọ́ṣe , bẹ́̀. 9 Mo sọ èyí fún yín , ẹnikẹ́ni ó kọ aya rẹ̀ sílẹ̀, láìṣe nítorí àgbèrè, ó fẹ́ ẹlòmíràn, ó ṣe panṣágà."

10 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ fún un , "̀rọ̀ báyìí láàrín ọkọ àti aya, ṣàǹfààní fún wa láti gbé ìyàwó."

11 Jesu dáhùn , "Gbogbo ènìyàn kọ́ gba ̀rọ̀ yìí, ṣe iye àwọn a ti fún. 12 Àwọn mìíràn jẹ́ akúra nítorí bẹ́̀ a wọn, àwọn mìíràn ń bẹ ènìyàn sọ wọn di bẹ́̀; àwọn mìíràn kọ̀ láti gbé ìyàwó nítorí ìjọba ̀run. Ẹni ó gbà á ó gbà á."

Àwọn ọmọdé àti Jesu

13 Lẹ́yìn náà a gbé àwọn ọmọ ọwọ́ sọ́dọ̀ Jesu, ó gbé ọwọ́ wọn, ó gbàdúrà fún wọn. Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ àwọn ó gbé wọn .

14 Ṣùgbọ́n Jesu dáhùn , "jẹ́ àwọn ọmọdé sọ́dọ̀ mi, ṣe wọn lẹ́kun, nítorí irú wọn ni ìjọba ̀run." 15 Lẹ́yìn náà, ó gbé ọwọ́ wọn, ó kúrò níbẹ̀.

̀dọ́mọkùnrin ọlọ́rọ̀

16 Ẹnìkan ó Jesu , "Olùkọ́, ohun rere ni èmi yóò ṣe, èmi ó ìyè àìnípẹ̀kun?"

17 Jesu a lóhùn , "Èéṣe ìwọ fi ń béèrè nípa ohun rere lọ́wọ́ mi. Ẹni kan ṣoṣo ni ó í ṣe ẹni rere. ìwọ fẹ́ ibi ìyè, pa àwọn òfin mọ́."

18 Ọkùnrin náà béèrè , "Àwọn wo ni òfin wọ̀nyí?"

Jesu dáhùn , " Ìwọ gbọdọ̀ pànìyàn; ìwọ gbọdọ̀ ṣe panṣágà; ìwọ gbọdọ̀ jalè; ìwọ gbọdọ̀ jẹ́rìí èké, 19 bọ̀wọ̀ fún baba àti ìyá rẹ. o fẹ́ aládùúgbò rẹ gẹ́gẹ́ ara rẹ.’ "

20 Ọmọdékùnrin náà tún , "Gbogbo òfin wọ̀nyí ni èmi ti ń pamọ́, ni nǹkan mìíràn èmi láti ṣe?"

21 Jesu fún un , "ìwọ fẹ́ di ẹni pípé, lọ ta ohun gbogbo ìwọ , o fi owó rẹ̀ tọrẹ fún àwọn aláìní. Ìwọ yóò ọrọ̀ ńlá ̀run. Lẹ́yìn náà, láti máa tọ̀ mi lẹ́yìn."

22 Ṣùgbọ́n nígbà ̀dọ́mọkùnrin náà gbọ́ èyí, ó kúrò níbẹ̀ pẹ̀ìbànújẹ́, nítorí ó ọrọ̀ púpọ̀.

23 Nígbà náà, Jesu fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "Lóòótọ́ ni mo fún yín , ó ṣòro fún ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba ̀run." 24 Mo tún fún yín , "Ó rọrùn fún ìbákasẹ láti wọ ojú abẹ́rẹ́ fún ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọ́run."

25 Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn gbọ́ èyí, ẹnu wọn gidigidi, wọ́n béèrè , "Ǹjẹ́ ta ni ó ha le ?"

26 Ṣùgbọ́n Jesu wọ́n, ó fún wọn , "Ènìyàn ni èyí ṣòro fún; ṣùgbọ́n fún Ọlọ́run ohun gbogbo ni ṣíṣe."

27 Peteru fún un , "Àwa ti fi ohun gbogbo sílẹ̀, a tẹ̀, ni yóò jẹ́ èrè wa?"

28 Jesu dáhùn , "Lóòótọ́ ni mo fún yín , Nígbà ìsọdọ̀tun ohun gbogbo, nígbà Ọmọ Ènìyàn yóò jókòó lórí ìtẹ́ ó lógo, dájúdájú, ̀yin ọmọ-ẹ̀yìn mi yóò jókòó lórí ìtẹ́ méjìlá láti ṣe ìdájọ́ ̀Israẹli méjìlá. 29 Àti ẹnikẹ́ni ó fi ilé tàbí arákùnrin tàbí arábìnrin tàbí baba tàbí ìyá tàbí àwọn ọmọ, tàbí ohun ìní rẹ̀ sílẹ̀ nítorí orúkọ , yóò gba ọgọọgọ́rùn-ún èrè rẹ̀ láyé, wọn ó tún jogún ìyè àìnípẹ̀kun. 30 Ṣùgbọ́n ̀pọ̀ àwọn ó síwájú nísinsin yìí ni yóò kẹ́yìn, àwọn ó kẹ́yìn ni yóò síwájú.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-