Pular para o conteúdo
Publicidade

Mateus 2

3 Nígbà ọba Herodu gbọ́ èyí, ìdààmú a àti gbogbo àwọn ara Jerusalẹmu pẹ̀rẹ̀. 4 Nígbà ó pe àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin jọ, ó bi wọ́n léèrè níbi ti a ó gbé Kristi? 5 2.5: Jh 7.42.Wọ́n , "Bẹtilẹhẹmu ti Judea, èyí ni ohun wòlíì ti kọ ìwé rẹ̀ ,

6 2.6: Mik 5.2. " Ṣùgbọ́n ìwọ Bẹtilẹhẹmu, ilẹ̀ Judea,

ìwọ kéré láàrín àwọn ọmọ-aládé Juda;

nítorí láti inú rẹ ni Baálẹ̀ kan yóò ti jáde,

ẹni ti yóò ṣe ìtọ́Israẹli, àwọn ènìyàn mi.’ "

7 Nígbà náà ni Herodu ọba pe àwọn amòye náà ìkọ̀kọ̀, ó wádìí ni ọwọ́ wọn, àkókò náà gan an wọ́n kọ́kọ́ ìràwọ̀. 8 Ó rán wọn lọ Bẹtilẹhẹmu, ó , "lọ ṣe ìwádìí fínní fínní ti ọmọ náà a . Lẹ́yìn i, padà sọ fún mi, èmi náà le lọ foríbalẹ̀ fún un."

Veja também