Publicidade

Mateus 21

Fífi ayọ̀ wọlé

1 wọ́n ti súnmọ́ Jerusalẹmu, wọ́n itòsí ìlú Betfage orí òkè Olifi, Jesu rán àwọn ọmọ-ẹ̀yìn méjì, 2 Ó fún wọn , "lọ ìletò ni tòsí yín, ̀yin yóò kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan ti wọ́n so pẹ̀ọmọ rẹ̀ lẹ́gbẹ̀́ rẹ̀. wọn, wọn fún mi. 3 ẹnikẹ́ni béèrè ìdí fi ń ṣe bẹ́̀, à , Olúwa fẹ́ lo wọn, òun yóò rán wọn lọ."

4 Èyí ṣẹlẹ̀ láti àsọtẹ́lẹ̀ wòlíì ṣẹ :

5 "sọ fún ọmọbìnrin Sioni ,

ó, ọba rẹ ń bọ̀ ̀dọ̀ rẹ,

ìrẹ̀lẹ̀, ó ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́,

àti lórí ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.’ "

6 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn náà lọ, wọ́n ṣe Jesu ti sọ fún wọn. 7 Wọ́n kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà pẹ̀ọmọ rẹ̀, wọ́n tẹ́ aṣọ e, Jesu si jókòó lórí rẹ̀. 8 ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn tẹ́ aṣọ wọn ojú ̀níwájú rẹ̀, ẹlòmíràn ṣẹ́ ̀ka igi wẹ́wẹ́ wọ́n tẹ́ wọn ojú ̀. 9 ̀pọ̀ ènìyàn ń lọ níwájú rẹ̀ àti lẹ́yìn rẹ̀ pẹ̀ń kígbe ,

"Hosana fún ọmọ Dafidi!"

"Olùbùkún ni fún ẹni ó ń bọ̀ orúkọ Olúwa!"

"Hosana ibi gíga jùlọ!"

10 Jesu ti ń wọ Jerusalẹmu, gbogbo ìlú tìtì, àwọn ènìyàn bẹ̀rẹ̀ í bi ara wọn , "Ta nìyìí?"

11 ̀pọ̀ ènìyàn dáhùn , "Èyí ni Jesu, wòlíì náà láti Nasareti ti Galili."

Jesu palẹ̀ Tẹmpili mọ́

12 Jesu wọ inú tẹmpili, Ó àwọn ti ń àti àwọn ń níbẹ̀ jáde. Ó tábìlì àwọn onípàṣípàrọ̀ owó dànù, àti tábìlì àwọn ó ń ta ẹyẹlé. 13 Ó fún wọn , "A à ti kọ ́ , Ilé àdúrà ni a ó máa pe ilé mi,ṣùgbọ́n ̀yin ti sọ ́ di ibùdó àwọn ọlọ́ṣà."

14 A àwọn afọ́àti àwọn arọ sọ́dọ̀ rẹ̀ tẹmpili, ó wọ́n láradá. 15 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin àwọn iṣẹ́ ìyanu ńlá wọ̀nyí, ti wọ́n tún ń gbọ́ àwọn ọmọdé ń kígbe nínú tẹmpili , "Hosana fún ọmọ Dafidi," inú wọn.

16 Wọ́n i , "Ǹjẹ́ ìwọ gbọ́ nǹkan àwọn ọmọdé wọ̀nyí ń sọ?"

Jesu dáhùn , "Bẹ́̀ ni, àbí ̀yin á ,

" Láti ẹnu àwọn ọmọdé àti àwọn ọmọ ọmú,

ni a ó ti máa yìn ?"

17 Ó fi wọ́n sílẹ̀, ó lọ Betani. Níbẹ̀ ni ó dúró òru náà.

Igi ̀pọ̀tọ́ gbẹ

18 òwúrọ̀ ó ṣe ń padà ìlú, ebi ń pa á. 19 Ó ṣàkíyèsí igi ̀pọ̀tọ́ kan lẹ́bàá ojú ̀, ó lọ ó bóyá àwọn èso lórí rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹyọ kan, ewé nìkan ni ó lórí rẹ̀. Nígbà náà ni ó fún igi náà , "èso tún so lórí rẹ mọ́ láti òní lọ àti títí láé." Lójúkan náà igi ̀pọ̀tọ́ náà gbẹ.

20 Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ èyí, ẹnu wọn, wọ́n béèrè , "Báwo ni igi ̀pọ̀tọ́ náà ṣe gbẹ kíákíá?"

21 Jesu fún wọn , "Lóòótọ́ ni mo fún yín, ̀yin ìgbàgbọ́ láìṣiyèméjì, nígbà náà ̀yin yóò ṣe irú ohun a ṣe igi ̀pọ̀tọ́, ̀yin yóò sọ fún òkè yìí , ipò padà sínú Òkun,yóò bẹ́̀. 22 ̀yin gbàgbọ́, ̀yin ohunkóhun béèrè nínú àdúrà gbà."

A béèrè àṣẹ Jesu ń

23 Jesu wọ tẹmpili, nígbà ó ń kọ́ni, àwọn olórí àlùfáà àti àwọn àgbàgbà Júù tọ̀ ́ . Wọ́n béèrè "nípa àṣẹ wo ni o fi ń ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí? Ta ni ó fún ni àṣẹ yìí?"

24 Jesu dáhùn ó fún wọn , "Èmi yóò si yin léèrè ohun kan, ̀yin sọ fún mi, nígbà náà èmi yóò sọ fún yín, àṣẹ Èmi fi ń ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí. 25 Níbo ni ìtẹ̀bọmi Johanu ti wa? Láti ̀run ni, tàbí láti ̀dọ̀ ènìyàn."

Wọ́n ara wọn gbèrò , "àwa láti ̀run ni, òun yóò fún wa , Èéha ti ṣe ̀yin fi gbà á gbọ́?’ 26 ìdàkejì, àwa sọ , Láti ̀dọ̀ ènìyàn, àwa bẹ̀ìjọ ènìyàn, nítorí gbogbo wọ́n ka Johanu wòlíì.’ "

27 Nítorí náà wọ́n Jesu lóhùn , "Àwa mọ̀."

Nígbà náà ni ó , "Nítorí èyí, èmi sọ àṣẹ èmi fi ń ṣe nǹkan wọ̀nyí fún yín.

Òwe àwọn ọmọ méjì

28 "ni nípa eléyìí? Ọkùnrin kan ti ó àwọn ọmọkùnrin méjì. Ó sọ fún èyí ̀gbọ́n , Ọmọ, lọ ṣiṣẹ́ nínú ọgbà àjàrà lónìí.

29 "Ó baba rẹ̀ lóhùn , Èmi í lọ,ṣùgbọ́n níkẹyìn ó ọkàn padà, ó lọ.

30 "Nígbà náà ni baba yìí tún sọ fún èyí àbúrò , Lọ ṣiṣẹ́ oko.Ọmọ náà sọ , Èmi yóò lọ, baba,ṣùgbọ́n lọ rárá.

31 "Nínú àwọn méjèèjì yìí, èwo ni ó ṣe ìfẹ́ baba wọn?"

Gbogbo wọn fohùn ṣọ̀kan , "Èyí ̀gbọ́n ni."

Jesu fún wọn , "Lóòótọ́ ni mo fún yín, àwọn agbowó òde àti àwọn panṣágà yóò wọ ìjọba ̀run síwájú yín. 32 Nítorí Johanu tọ́ yin láti fi ̀òdodo hàn yín, ṣùgbọ́n ̀yin gbà á gbọ́, ṣùgbọ́n àwọn agbowó òde àti àwọn panṣágà ronúpìwàdà, ó tilẹ̀ ṣe àwọn ohun ń ṣẹlẹ̀ wọ̀nyí, kọ̀ láti ronúpìwàdà, gbà á gbọ́."

Òwe àwọn ayálégbé

33 "gbọ́ òwe mìíràn, Baálé ilé kan ó gbin ọgbà àjàrà, ó ṣe ọgbà yìí , ó ibi ìfúntí sínú rẹ̀, ó kọ́ ilé ìṣọ́. Ó fi oko náà ṣe àgbàtọ́fún àwọn àgbẹ̀ kan, ó lọ ìrìnàjò. 34 Nígbà ti àkókò ìkórè súnmọ́, ó rán àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ àwọn àgbẹ̀ náà láti gba èyí ti ó jẹ tirẹ̀ .

35 "Ṣùgbọ́n àwọn alágbàtọ́àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀, wọn lu ẹni kìn-ín-ní, wọn pa èkejì, wọ́n si sọ ̀kẹta òkúta. 36 Ó tún rán àwọn ọmọ ̀dọ̀ mìíràn àwọn ó ju ti ìṣáájú lọ. Wọ́n túnṣe ti àkọ́kọ́ àwọn wọ̀nyí pẹ̀. 37 Níkẹyìn, baálé ilé yìí rán ọmọ rẹ̀ pàápàá wọn. Ó , Wọn yóò bu ọlá fún ọmọ mi.

38 "Ṣùgbọ́n àwọn alágbàtọ́wọ̀nyí ti ọmọ náà lókèèrè, wọ́n fún ara wọn , Èyí ni àrólé náà. , jẹ́ a pa á, a jogún rẹ̀.’ 39 Wọ́n wọ́ jáde kúrò nínú ọgbà àjàrà náà, wọ́n pa á.

40 "Ǹjẹ́ nígbà olúwa ọgbà àjàrà , ni yóò ṣe àwọn olùṣọ́gbà wọ̀n-ọn-nì?"

41 Wọ́n , "Òun yóò pa àwọn ènìyàn búburú náà run, yóò fi ọgbà àjàrà rẹ̀ fún àwọn alágbàtọ́mìíràn yóò fún un èso tirẹ̀ lásìkò ìkórè."

42 Jesu fún wọ́n , "Àbí ̀yin á nínú Ìwé Mímọ́ :

" Òkúta àwọn ̀mọ̀kọ̀sílẹ̀,

ni ó di pàtàkì igun ilé;

iṣẹ́ Olúwa ni èyí,

ó jẹ́ ìyanu ojú wa?

43 "Nítorí náà èmi fún yín, a ó gba ìjọba Ọlọ́run lọ́wọ́ yín, a ó fi fún àwọn orílẹ̀-èdè yóò máa èso rẹ̀ . 44 Ẹni ó ṣubú lu òkúta yìí yóò di fífọ́, ṣùgbọ́n ẹni òun ṣubú yóò lọ̀ ́ lúúlúú."

45 Nígbà àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi gbọ́ òwe Jesu, wọ́n mọ̀ ó ń sọ̀rọ̀ nípa àwọn. 46 Wọn ̀láti un, ṣùgbọ́n wọn bẹ̀̀pọ̀ ènìyàn wọ́n gba Jesu gẹ́gẹ́ wòlíì.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-