Publicidade

Mateus 26

Ìdìtẹ̀ mọ́ Jesu

1 Nígbà Jesu ti parí ̀rọ̀ wọ̀nyí pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó fún wọn , 2 "̀yin mọ̀ ọjọ́ méjì i, àjọ ìrékọjá yóò bẹ̀rẹ̀. Àti , a ó fi Ọmọ Ènìyàn wọn lọ́wọ́, a ó kàn mọ́ àgbélébùú."

3 àsìkò Jesu ń sọ̀rọ̀ yìí, àwọn olórí àlùfáà àti àwọn àgbàgbà ara wọn jọ ààfin olórí àlùfáà náà à ń Kaiafa. 4 Láti gbèrò àwọn ̀wọ́n yóò fi Jesu pẹ̀̀tàn, wọn pa á. 5 Ṣùgbọ́n wọ́n fohùn ṣọ̀kan , "í ṣe lásìkò àsè àjọ ìrékọjá, nítorí rògbòdìyàn yóò ṣẹlẹ̀."

A fi òróró kun Jesu lára Betani

6 Nígbà Jesu Betani ilé ọkùnrin à ń Simoni adẹ́tẹ̀. 7 ó ti ń jẹun, obìnrin kan sọ́dọ̀ rẹ̀ pẹ̀alabasita òróró ìkunra iyebíye, ó á i lórí.

8 Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn i, inú wọn. Wọ́n , "Irú ìfowóṣòfò wo ni èyí? 9 Èéha ti ṣe, obìnrin yìí ìbá á owó púpọ̀, a fi owó náà fún àwọn aláìní."

10 Jesu ti mọ èrò ọkàn wọn, ó , "Èéṣe ti ̀yin fi ń obìnrin yìí lẹ́bi? Ó ṣe ohun ó dára fún mi. 11 ̀yin yóò àwọn aláìní láàrín yín nígbà gbogbo, ṣùgbọ́n, ̀yin le mi nígbà gbogbo. 12 Nípa dída òróró ìkunra yìí mi lára, òun ń ṣe èyí fún ìsìnkú mi ni. 13 Lóòótọ́ ni mo fún yín, a ó máa ṣe ìrántí rẹ̀ nígbà gbogbo fún ìṣesí rẹ̀ yìí. Níbikíbi a ti wàásù ìyìnrere yìí gbogbo àgbáyé ni a ó ti sọ ìtàn ohun obìnrin yìí ṣe."

Judasi gbà láti fi Jesu hàn

14 Nígbà náà ni ̀kan nínú àwọn aposteli méjìlá ti à ń Judasi Iskariotu lọ sọ́dọ̀ àwọn olórí àlùfáà. 15 Òun béèrè , "ni ̀yin yóò san fún mi mo fi Jesu yín lọ́wọ́?" Wọ́n fún un ọgbọ́n owó fàdákà. Ó gbà á. 16 Láti ìgbà náà lọ ni Judasi ti bẹ̀rẹ̀ i ̀láti á wọn lọ́wọ́.

Oúnjẹ alẹ́ ìkẹyìn

17 ọjọ́ kìn-ín-ní àjọ àìwúkàrà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn tọ Jesu , "Níbo ni ìwọ fẹ́ a pèsè sílẹ̀ láti jẹ àsè ìrékọjá?"

18 Jesu dáhùn , "wọ ìlú lọ, ̀yin yóò ọkùnrin kan, fún un , Olùkọ́ wa , àkókò mi ti . Èmi yóò jẹ àsè ìrékọjá pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mi ilé rẹ.’ " 19 Nítorí náà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn náà ṣe gẹ́gẹ́ Jesu ti sọ fún wọn. Wọ́n tọ́oúnjẹ àsè ti ìrékọjá níbẹ̀.

20 àṣálẹ́ ọjọ́ kan náà, Jesu ti jókòó pẹ̀àwọn méjìlá, 21 nígbà wọ́n ń jẹun, ó , "Lóòótọ́ ni mo fún yín, ̀kan nínú yín yóò fi hàn."

22 Ìbànújẹ́ bo ọkàn wọn nígbà wọ́n gbọ́ èyí. Wọ́n bẹ̀rẹ̀ bi í , "Olúwa, èmi ni ?"

23 Jesu dáhùn , "Ẹni ti ó mi tọwọ́ bọ inú àwo, ni yóò fi mi hàn. 24 Ọmọ Ènìyàn ń lọ a ti kọ̀nípa rẹ̀: ṣùgbọ́n ègbé ni fún ọkùnrin náà lọ́wọ́ ẹni a ó ti fi Ọmọ Ènìyàn hàn! Ìbá kúkú sàn fún ẹni náà, a ."

25 Judasi, ẹni ó fi í hàn pẹ̀béèrè , "Rabbi, èmi ni ?"

Jesu a lóhùn , "Ìwọ i."

26 wọ́n ti ń jẹun, Jesu ìwọ̀n àkàrà kékeré kan, lẹ́yìn ó ti gbàdúrà i, ó ú, Ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, Ó , "Gbà, jẹ; nítorí èyí ni ara mi."

27 Bákan náà, ó ago wáìnì, ó dúpẹ́ fún un, ó gbé e fún wọn. Ó , "gbogbo yín mu nínú rẹ̀. 28 Nítorí èyí ni ̀jẹ̀ mi májẹ̀tuntun, a ta sílẹ̀ fún ìdáríjì ̀ṣẹ̀ ̀pọ̀ ènìyàn. 29 kíyèsi àwọn ̀rọ̀ mi. Èmi yóò tún mu nínú ọtí wáìnì yìí mọ́ títí di ọjọ́ náà èmi yóò mu ún tuntun pẹ̀yín ìjọba Baba mi."

30 Wọ́n kọ orin kan, lẹ́yìn náà wọ́n lọ sórí òkè Olifi.

Jesu sọ Peteru yóò sẹ́ òun

31 Nígbà náà ni Jesu fún wọn , "Gbogbo yín ni yóò kọsẹ̀ lára mi òru òní. Nítorí a ti kọ ́ :

" Èmi yóò kọlu olùṣọ́-àgùntàn

a ó agbo àgùntàn náà kiri.

32 Ṣùgbọ́n lẹ́yìn mo dìde, èmi yóò ṣáájú yín lọ Galili."

33 Peteru a lóhùn , "gbogbo ènìyàn tilẹ̀ kọ̀ ́ sílẹ̀, èmi yóò ṣe bẹ́̀."

34 Jesu fún un , "Lóòótọ́ ni mo fún , òru yìí, àkùkọ ó kọ, ìwọ yóò sẹ́ mi nígbà mẹ́ta."

35 Peteru fún un , "ó tilẹ̀ jẹ́ láti pẹ̀, èmi jẹ́ sẹ́ ." Gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni gbogbo àwọn ọmọ-ẹ̀yìn .

Jesu Getsemane

36 Nígbà náà ni Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ lọ ibi kan ti à ń ọgbà Getsemane, ó fún wọn , "jókòó níhìn-ín nígbà mo lọ gbàdúrà lọ́hùn ún ni." 37 Ó Peteru àti àwọn ọmọ Sebede méjèèjì Jakọbu àti Johanu pẹ̀rẹ̀, ìrora àti ìbànújẹ́ bẹ̀rẹ̀ gba ọkàn rẹ̀. 38 Nígbà náà ni ó fún wọn , "Ọkàn mi gbọgbẹ́ pẹ̀ìbànújẹ́ títí ojú ikú, dúró níhìn-ín yìí, máa ṣọ́pẹ̀mi."

39 Òun lọ iwájú díẹ̀ i, ó dojúbolẹ̀, ó gbàdúrà , "Baba mi, ó ṣe é ṣe, jẹ́ a ago yìí mi lórí kọjá, ṣùgbọ́n ìfẹ́ tìrẹ ni mo fẹ́ ó ṣẹ, í ṣe ìfẹ́ tèmi."

40 ó ti padà sọ́dọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ mẹ́tẹ̀̀ta, ó wọn, wọ́n ń sùn. Ó kígbe , "Peteru, ̀yin tilẹ̀ mi ṣọ́fún wákàtí kan? 41 máa ṣọ́ra, máa gbàdúrà ̀yin ba à bọ́ sínú ìdẹwò. Nítorí ̀ń fẹ́ nítòótọ́, ṣùgbọ́n ó ṣe àìlera fún ara."

42 Ó tún fi wọ́n sílẹ̀ nígbà kejì, ó gbàdúrà , "Baba mi, ago yìí mi lórí kọjá ṣe mo mu ún, ìfẹ́ tìrẹ ni a ṣe."

43 Nígbà ó tún padà sọ́dọ̀ wọn, Ó i wọn ń sùn, nítorí ojú wọn kún fún oorun. 44 Nítorí náà, ó fi wọn sílẹ̀ ó tún padà lọ láti gbàdúrà nígbà kẹta, ó ń ohun kan náà.

45 Nígbà náà ni ó tọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , ó , "Àbí ̀yin ń sùn síbẹ̀, ti ń sinmi? ó wákàtí náà ti a ó fi Ọmọ Ènìyàn àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ lọ́wọ́. 46 dìde! jẹ́ a máa lọ! ó, ẹni yóò fi mi hàn ń bọ̀ !"

A Jesu

47 ó ti ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, Judasi, ̀kan nínú àwọn méjìlá pẹ̀̀pọ̀ ènìyàn pẹ̀idà àti kùmọ̀ lọ́wọ́ wọn, wọ́n ti ̀dọ̀ àwọn olórí àlùfáà àti àgbàgbà Júù . 48 Ẹni ó fi í hàn ti fi àmì fún wọn, , "Ẹnikẹ́ni mo fi ẹnu ẹnu, òun náà ni; un." 49 Nísinsin yìí, Judasi tààrà sọ́dọ̀ Jesu, ó , "Àlàáfíà, Rabbi!" Ó fi ẹnu ó ẹnu.

50 Jesu , "̀rẹ́, ni nǹkan ìwọ ."

Àwọn ìyókù sún síwájú wọ́n Jesu. 51 ó, ̀kan nínú àwọn ó pẹ̀Jesu na ọwọ́ rẹ̀, ó fa idà yọ, ó ̀kan i ṣe ọmọ ̀dọ̀ olórí àlùfáà, ó e etí sọnù.

52 Jesu fún un , "Fi idà rẹ bọ àkọ̀ nítorí àwọn ó ń fi idà pa ni a ó fi idà pa. 53 Ìwọ mọ̀ èmi béèrè lọ́wọ́ Baba mi ó fún mi ju légíónì angẹli méjìlá? Òun yóò fi wọ́n ránṣẹ́ lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀. 54 Ṣùgbọ́n mo ṣe eléyìí ̀wo ni a ó fi Ìwé Mímọ́ ṣẹ, èyí ó ti sọ ohun ó ṣẹlẹ̀ nísinsin yìí?"

55 Nígbà náà ni Jesu fún ìjọ ènìyàn náà , "Ǹjẹ́ èmi ni ̀daràn ti múra pẹ̀idà àti kùmọ̀ mi? rántí mo ti pẹ̀yín, mo ń kọ́ yín lójoojúmọ́ nínú tẹmpili, ̀yin mi nígbà náà. 56 Ṣùgbọ́n gbogbo wọ̀nyí ń ṣẹlẹ̀ ̀rọ̀ a ẹnu àwọn wòlíì sọ, a kọ sínú Ìwé Mímọ́ ṣẹ." Nígbà yìí gan an ni gbogbo àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ti kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n sálọ.

Níwájú Sahẹndiri

57 Àwọn ó Jesu á lọ ilé Kaiafa, olórí àlùfáà, níbi ti àwọn olùkọ́ òfin àti gbogbo àwọn àgbàgbà Júù péjọ . 58 Ṣùgbọ́n Peteru ń tẹ̀e lókèèrè. Òun àgbàlá olórí àlùfáà. Ó wọlé, ó jókòó pẹ̀àwọn olùṣọ́. Ó ń dúró láti ri ohun yóò ṣẹlẹ̀ Jesu.

59 Nígbà náà ni àwọn olórí àlùfáà àti gbogbo ìgbìmọ̀ Júù ilé ẹjọ́ ó ga jùlọ ti Júù péjọ síbẹ̀, wọ́n àwọn ẹlẹ́rìí yóò purọ́ mọ́ Jesu, a ba à ẹjọ́ mọ́ ọn lẹ́sẹ̀, eléyìí yóò yọrí si ìdájọ́ ikú fún un. 60 ó tilẹ̀ jẹ́ àwọn ẹlẹ́rìí èké dìde, ṣùgbọ́n wọn ohun kan.

Níkẹyìn, àwọn ẹlẹ́rìí méjì dìde. 61 Wọn , "Ọkùnrin yìí sọ , Èmi lágbára láti tẹmpili Ọlọ́run lulẹ̀, èmi yóò tún un mọ ọjọ́ mẹ́ta.’ "

62 Nígbà náà ni olórí àlùfáà dìde, ó fún Jesu , "̀yìí ń kọ́? Ìwọ sọ bẹ́̀ tàbí ìwọ sọ bẹ́̀?" 63 Ṣùgbọ́n Jesu dákẹ́ rọ́rọ́.

Nígbà náà ni olórí àlùfáà fún un , "Mo fi ́ orúkọ Ọlọ́run alààyè, ó sọ fún wa, ìwọ í ṣe Kristi Ọmọ Ọlọ́run."

64 Jesu dáhùn , "Bẹ́̀ ni, ìwọ ." Ṣùgbọ́n mo fún gbogbo yín. "̀yin yóò Ọmọ Ènìyàn ti yóò jókòó lọ́wọ́ ̀tún alágbára, yóò máa bọ̀ láti inú ìkùùkuu."

65 Nígbà náà ni olórí àlùfáà fa aṣọ òun tìkára rẹ̀ ya. Ó kígbe , "̀rọ̀-òdì! ni a tún ń ẹlẹ́rìí fún? Gbogbo yín ti gbọ́ ̀rọ̀-òdì rẹ̀. ni ìdájọ́ yín?" 66 Ki ni ti èyí .

Gbogbo wọn kígbe lọ́hùn kan , "Ó jẹ̀bi ikú!"

67 Wọ́n tu itọ́ i ojú. Wọ́n kàn án lẹ́ṣẹ̀́. Àwọn ẹlòmíràn gbá a lójú. 68 Wọ́n , "Sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún wa! Ìwọ Kristi, ta ni ẹni ó ń ́?"

Peteru sẹ́ Jesu

69 Lákòókò yìí, Peteru ti ń jókòó àgbàlá, ọmọbìnrin kan tọ̀ ́ , ó , "Ìwọ pẹ̀Jesu ti Galili."

70 Ṣùgbọ́n Peteru sẹ̀ ojú gbogbo wọn , "Èmi tilẹ̀ mọ ohun ń sọ nípa rẹ̀."

71 Lẹ́yìn èyí, ìta ẹnu-ọ̀, ọmọbìnrin mìíràn tún i, ó fún àwọn ó dúró yíká , "Ọkùnrin yìí pẹ̀Jesu ti Nasareti."

72 Peteru tún sẹ́ lẹ́̀kejì pẹ̀ìbúra , "Èmi tilẹ̀ mọ ọkùnrin náà rárá."

73 Nígbà ó pẹ́ díẹ̀, àwọn ọkùnrin ó ń dúró níbi ìran yìí tọ̀ ́ , wọ́n fún Peteru , "Lóòótọ́, ìwọ jẹ́ ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn, àwa mọ̀ ́n. Èyí wa lójú nípa àmì ohùn rẹ̀ ó ń ti ẹnu rẹ jáde."

74 Peteru tún bẹ̀rẹ̀ í búra ó fi ara rẹ̀ , "Mo èmi mọ ọkùnrin yìí rárá."

Lójúkan náà àkùkọ kọ. 75 Nígbà náà ni Peteru rántí nǹkan Jesu ti sọ , "àkùkọ ó kọ, ìwọ yóò sẹ́ mi nígbà mẹ́ta." Òun bọ́ òde, ó sọkún kíkorò.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-