Publicidade

Romanos 13

Ṣíṣe ìgbọ́ràn àwọn aláṣẹ

1 olúkúlùkù ọkàn ó foríbalẹ̀ fún àwọn aláṣẹ ó ipò gíga. Nítorí àṣẹ kan, ṣe láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ; àwọn aláṣẹ ó , láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ni a ti lànà rẹ̀ . 2 Nítorí ẹni ó tàpá àṣẹ, ó tàpá ìlànà Ọlọ́run; àwọn ẹni ó ba ń tàpá, yóò gba ̀bi fún ara wọn. 3 Nítorí àwọn ìjòyè láti dẹ́rùbà àwọn ń ṣe rere, ṣe àwọn ń ṣe búburú. Ǹjẹ́ ìwọ ha fẹ́ di òmìnira kúrò nínú ̀ẹni ipò àṣẹ. Nítorí náà ṣe èyí ó dára, ìwọ yóò gba ìyìn láti ̀dọ̀ rẹ̀. 4 Nítorí ìránṣẹ́ Ọlọ́run ni i ṣe fún ́ rere. Ṣùgbọ́n ìwọ ń ṣé búburú, máa bẹ̀, nítorí gbé idà náà lásán. Nítorí ìránṣẹ́ Ọlọ́run í ṣe, olùgbẹ̀san láti ṣiṣẹ́ ìbínú lára ẹni ń ṣe búburú. 5 Nítorí náà, ̀yin gbọdọ̀ tẹríba fún àwọn aláṣẹ, í ṣe nítorí ti ìbínú nìkan, ṣùgbọ́n nítorí ̀ọkàn pẹ̀.

6 Nítorí ìdí èyí, san owó òde pẹ̀, nítorí ìránṣẹ́ Ọlọ́run ni wọ́n, èyí náà ni wọ́n ń bojútó nígbà gbogbo. 7 san ohun ó tọ́ fún ẹni gbogbo: owó òde fún ẹni owó òde í ṣe tirẹ̀: owó bodè fún ẹni owó bodè í ṣe tirẹ̀: ̀fún ẹni ̀í ṣe tirẹ̀; ọlá fún ẹni ọlá í ṣe tirẹ̀.

jẹ gbèsè ìfẹ́

8 ṣe jẹ ẹnikẹ́ni gbèsè ohun kan, ṣe a fẹ́ ọmọ ẹnìkejì ẹni, nítorí ẹni ó fẹ́ ọmọnìkejì rẹ̀, ó òfin . 9 Àwọn òfin, "Ìwọ gbọdọ̀ ṣe panṣágà," "Ìwọ gbọdọ̀ pànìyàn," "Ìwọ gbọdọ̀ jalè," "Ìwọ gbọdọ̀ jẹ́rìí èké," "Ìwọ gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò," òfin mìíràn , ni a papọ̀ ṣọ̀kan nínú òfin kan yìí: "Fẹ́ ẹnìkéjì rẹ gẹ́gẹ́ ara rẹ̀." 10 Ìfẹ́ í ṣe ohun búburú ọmọnìkejì rẹ̀, nítorí náà ìfẹ́ ni àkójá òfin.

Ọjọ́ Olúwa fẹ́rẹ

11 Àti èyí, ̀yin ti mọ àkókò , ó ti wákàtí nísinsin yìí fún yín láti lójú orun, nítorí nísinsin yìí ni ìgbàlà wa súnmọ́ etílé ju ìgbà àwa ti gbàgbọ́ lọ. 12 Òru kọjá tan, ilẹ̀ fẹ́rẹ mọ́: nítorí náà jẹ́ a bọ́ ara iṣẹ́ òkùnkùn sílẹ̀, a gbé ìhámọ́ra ìmọ́lẹ̀ wọ̀. 13 Jẹ́ a rin ìrìn títọ́, ̀sán; í ṣe ìréde òru àti ìmutípara, í ṣe ni ìwà èérí àti wọ̀bìà, í ṣe ìjà àti ìlara. 14 Ṣùgbọ́n gbé Jesu Kristi Olúwa wọ̀, pèsè fún ara, láti máa ìfẹ́kúfẹ̀́ rẹ̀ ṣẹ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-