Pular para o conteúdo
Publicidade

Romanos 2

Ìdájọ́ òdodo Ọlọ́run

1 2.1: Ro 14.22. Nítorí náà, aláìríwí ni ẹnikẹ́ni ó ó jẹ́ ń ni lẹ́jọ́, nítorí nínú ohun ìwọ ń ṣe ìdájọ́ ẹlòmíràn, ìwọ ń ara rẹ lẹ́bi; nítorí ìwọ ń dájọ́ ń ṣe ohun kan náà nínú èyí ìwọ ń ni lẹ́jọ́. 2 Ṣùgbọ́n àwa mọ̀ ìdájọ́ Ọlọ́run jẹ́ òtítọ́ si gbogbo àwọn ó ń ṣe irú ohun báwọ̀nyí. 3 Nítorí ìwọ ń ṣe ènìyàn lásán ń ṣe ìdájọ́ àwọn ń ṣe irú ohun báwọ̀nyí, ìwọ tìkára rẹ ń ṣe bẹ́̀, ìwọ ro èyí ìwọ o yọ nínú ìdájọ́ Ọlọ́run ? 4 2.4: Ef 1.7; 2.7; Fp 4.19; Kl 1.27.Tàbí ìwọ ń gàn ọrọ̀ oore àti ìpamọ́ra àti sùúrù rẹ̀? Ìwọ ha mọ̀ oore Ọlọ́run ni ó ń ́ lọ ìrònúpìwàdà?

5 Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ líle àti àìronúpìwàdà ọkàn rẹ̀, ìwọ ń to ìbínú jọ fún ara rẹ de ọjọ́ ìbínú àti ìfihàn ìdájọ́ òdodo Ọlọ́run. 6 2.6: Mt 16.27; 1Kọ 3.8; 2Kọ 5.10; If 22.12.Ọlọ́run yóò san án fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ iṣẹ́ rẹ̀. 7 Àwọn ẹni ń fi sùúrù nínú rere ṣíṣe, ògo àti ọlá àti àìdíbàjẹ́ ni yóò fi ìyè àìnípẹ̀kun fún. 8 Ṣùgbọ́n fún àwọn onímọ̀-tara-ẹni-nìkan, wọn gba òtítọ́ gbọ́, ṣùgbọ́n wọn ń tẹ̀̀búburú, wọn yóò ìrírí ìrunú àti ìbínú rẹ̀. 9 Ìpọ́njú àti ìrora, yóò lórí olúkúlùkù ọkàn ènìyàn ń hùwà ibi: ti Júù ṣáájú, àti àwọn Helleni pẹ̀; 10 ṣùgbọ́n ògo, àti ọlá, àti àlàáfíà, fún olúkúlùkù ẹni ń hùwà rere, fún Júù, ṣáájú àti fún àwọn Helleni pẹ̀. 11 Nítorí Ọlọ́run í ṣe ojúsàájú ènìyàn.

12 2.12: Ro 3.19; 1Kọ 9.21. Gbogbo àwọn ó ṣẹ̀ àìlófin wọn ó ṣègbé láìlófin, àti iye àwọn ó ṣẹ̀ lábẹ́ òfin, àwọn ni a ó fi òfin lẹ́jọ́. 13 2.13: Jk 1.22-23,25.Nítorí í ṣe àwọn olùgbọ́ òfin ni ẹni ìdáláre lọ́dọ̀ Ọlọ́run, ṣùgbọ́n àwọn olùṣe òfin ni a ó láre. 14 Nítorí nígbà àwọn aláìkọlà, òfin, ṣe ohun ó nínú òfin nípa ìwà ̀, àwọn wọ̀nyí, jẹ́ òfin fún ara wọn wọn tilẹ̀ òfin. 15 Àwọn ẹni ó fihàn , a kọ̀iṣẹ́ òfin wọn lọ́kàn, ̀ọkàn wọn pẹ̀tún ń jẹ́ wọn lẹ́rìí, àti , èrò ọkàn wọn ó jẹ́ ̀ìfinisùn, ń gbè wọ́n lẹ́yìn ìsinsin yìí. 16 2.16: Su 12.14; Ro 16.25; 1Kọ 4.5.Èyí yóò farahàn ọjọ́ náà nígbà Ọlọ́run yóò tipasẹ̀ Jesu Kristi ṣe ìdájọ́ àwọn àṣírí ènìyàn gẹ́gẹ́ ìyìnrere mi.

Àwọn Júù àti òfin

17 Ṣùgbọ́n a ń pe ìwọ Júù, o sinmi òfin, o ń ṣògo nínú ìbálòpọ̀ rẹ̀ Ọlọ́run, 18 2.18: Fp 1.10.o mọ ìfẹ́ rẹ̀, o fọwọ́ohun ó dára jùlọ, nítorí a ti kọ́ òfin; 19 o ara rẹ lójú ìwọ ni amọ̀àwọn afọ́, ìmọ́lẹ̀ fún àwọn ó ni òkùnkùn, 20 2.20: Ro 6.17; 2Tm 1.13.Olùkọ́ àwọn aláìmòye, olùkọ́ àwọn ọmọdé, ẹni ó ètò ìmọ̀ àti òtítọ́ òfin lọ́wọ́. 21 2.21: Mt 23.3-4.Ǹjẹ́ ìwọ o ń kọ́ ẹlòmíràn, ìwọ kọ́ ara rẹ? Ìwọ ó ń wàásù ènìyàn jalè, ìwọ ha ń jalè ? 22 Ìwọ o , ènìyàn ṣe panṣágà, ìwọ ń ṣe panṣágà ? Ìwọ o kórìíra òrìṣà, ìwọ ń ja tẹmpili olè ? 23 Ìwọ ti ń ṣògo nínú òfin, ìwọ ha ń bu Ọlọ́run ni ọlá nípa rírú òfin? 24 2.24: Isa 52.5.Nítorí gẹ́gẹ́ a ti kọ ́, "Orúkọ Ọlọ́run à di ìsọ̀rọ̀-òdì láàrín àwọn aláìkọlà nítorí yín."

25 2.25: Jr 9.25. Nítorí ìkọlà èrè nítòótọ́, ìwọ pa òfin mọ́; ṣùgbọ́n ìwọ jẹ́ arúfin, ìkọlà rẹ di àìkọlà. 26 2.26: 1Kọ 7.19; Ap 10.35.Nítorí náà àwọn aláìkọlà pa ìlànà òfin mọ́, a yóò ha wọ́n àwọn a kọ nílà ? 27 2.27: Mt 12.41.Aláìkọlà nípa àdánidá, ó pa òfin mọ́, yóò ̀bi fún ìwọ ó jẹ́ arúfin nípa ti àkọsílẹ̀ òfin àti ìkọlà.

28 2.28: Mt 3.9; Jh 8.39; Ro 9.6-7; Ga 6.15. í ṣe èyí ó farahàn òde ni Júù, bẹ́̀ ni í ṣe èyí ó farahàn ara ni ìkọlà. 29 2.29: 2Kọ 3.6; Fp 3.3; Kl 2.11; 1Pt 3.4.Ṣùgbọ́n Júù ti inú ni Júù, àti ìkọlà ni ti ọkàn nínú ̀í ṣe ti àkọsílẹ̀, ìyìn ẹni lọ́dọ̀ ènìyàn, ṣe lọ́dọ̀ Ọlọ́run.

Veja também