Publicidade

Romanos 4

Abrahamu gba ìdáláre nípa ìgbàgbọ́

1 Ǹjẹ́ kín ni àwa ó ha nípa Abrahamu, baba wa ti o ṣàwárí èyí? Májẹ̀láéláé jẹ́rìí i , a gba Abrahamu nípa ìgbàgbọ́. 2 4.2: 1Kọ 1.31.Nítorí a Abrahamu láre nípa iṣẹ́, ó ohun ìṣògo; ṣùgbọ́n í ṣe níwájú Ọlọ́run. 3 4.3: Gẹ 15.6; Ro 4.9,22; Ga 3.6; Jk 2.23.Ìwé Mímọ́ ha ti ? "Abrahamu gba Ọlọ́run gbọ́, a á òdodo fún un."

4 4.4: Ro 11.6. Ǹjẹ́ fún ẹni ó ṣiṣẹ́, a ka èrè náà oore-ọ̀fẹ́ ṣe ̀tọ́ rẹ̀. 5 4.5: Ro 3.22.Ṣùgbọ́n fún ẹni ṣiṣẹ́, ó ń gba ẹni ó ń ènìyàn búburú láre gbọ́, a ka ìgbàgbọ́ rẹ̀ òdodo. 6 Gẹ́gẹ́ Dafidi pẹ̀ti pe olúwa rẹ̀ náà ẹni ìbùkún, ẹni Ọlọ́run ka òdodo fún láìsí ti iṣẹ́.

7 4.7: Sm 32.1-2. , "Ìbùkún ni fún àwọn

ẹni a dárí ìrékọjá wọn ,

a bo ̀ṣẹ̀ wọn mọ́lẹ̀.

8 Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà

ẹni Olúwa ka ̀ṣẹ̀ lọ́rùn."

9 Ìbùkún yìí ha jẹ́ ti àwọn akọlà nìkan, tàbí ti àwọn aláìkọlà pẹ̀? Nítorí a , Abrahamu gba Ọlọ́run gbọ́, a á òdodo fún un. 10 Báwo ni a ṣe á i? Nígbà ó ìkọlà tàbí àìkọlà? í ṣe ni ìkọlà, ṣùgbọ́n àìkọlà ni. 11 4.11: Gẹ 17.10; Ro 3.22,30.Ó gbé àmì ìkọlà àti èdìdì òdodo ìgbàgbọ́ ó nígbà ó àìkọlà ó ṣe baba gbogbo àwọn ó gbàgbọ́, a tilẹ̀ kọ wọ́n ilà a ka òdodo wọn pẹ̀. 12 Àti baba àwọn ìkọlà í ṣe a kàn kọlà fún nìkan, ṣùgbọ́n tiwọn ń tẹ̀àpẹẹrẹ ìgbàgbọ́ baba wa Abrahamu , a kọ ́ nílà.

13 4.13: Gẹ 17.4-6; 22.17-18; Ga 3.29. Ìlérí fún Abrahamu àti fún irú-ọmọ rẹ̀, ni , wọn ó jogún ayé, í ṣe nípa òfin ṣe nípa òdodo ti ìgbàgbọ́. 14 4.14: Ga 3.18.Nítorí àwọn ń ṣe ti òfin jẹ ajogún, ìgbàgbọ́ di asán, ìlérí di aláìlágbára. 15 4.15: Ga 3.10.Nítorí òfin ń ṣiṣẹ́ ìbínú, ṣùgbọ́n ibi òfin , ìrúfin níbẹ̀.

16 Nítorí náà ni ó ṣe gbé e ka orí ìgbàgbọ́, ìlérí náà a sinmi oore-ọ̀fẹ́, a un gbogbo irú-ọmọ lójú, í ṣe fún àwọn ń pa òfin mọ́ nìkan, ṣùgbọ́n ṣe pẹ̀fún àwọn ti ó pín nínú ìgbàgbọ́ Abrahamu, ẹni í ṣe baba gbogbo wa pátápátá, 17 4.17: Gẹ 17.5; Jh 5.21.Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ , "Mo ti fi ́ ṣe baba orílẹ̀-èdè púpọ̀." Níwájú Ọlọ́run ẹni òun gbàgbọ́, ẹni ó sọ òkú di ààyè, ó àwọn ohun ẹni wọ́n .

18 4.18: Gẹ 15.5. Nígbà ìrètí mọ́, Abrahamu gbàgbọ́ nínú ìrètí bẹ́̀ ni ó di baba orílẹ̀-èdè púpọ̀, gẹ́gẹ́ èyí a fún un , "Báyìí ni irú-ọmọ rẹ̀ yóò ." 19 4.19: Hb 11.12; Gẹ 17.17; 18.11.Ẹni rẹ̀wẹ̀nínú ìgbàgbọ́, nígbà ó mọ pe ara òun tìkára rẹ̀ ó ti tan, nítorí ó ẹni ìwọ̀n ọgọ́rùn-ún ọdún, àti nígbà ó ro ti yíyàgàn inú Sara. 20 fi àìgbàgbọ́ ṣiyèméjì nípa ìlérí Ọlọ́run; ṣùgbọ́n ó lágbára i nínú ìgbàgbọ́ ó ti fi ògo fún Ọlọ́run, 21 pẹ̀ìdánilójú kíkún , Ọlọ́run ṣe ohun ó ti ṣe ìlérí rẹ̀. 22 4.22: Ro 4.3.Nítorí náà ni a ṣe á òdodo fún un. 23 4.23-24: Ro 15.4; 1Kọ 9.10; 10.11.Ṣùgbọ́n ̀rọ̀ náà, "A á òdodo fún un," ni a kọ í ṣe nítorí tirẹ̀ nìkan. 24 Ṣùgbọ́n nítorí tiwa pẹ̀. A ó á fún wa, àwa gba ẹni ó gbé Jesu Olúwa wa dìde kúrò nínú òkú gbọ́. 25 4.25: Ro 8.32.Ẹni a pa fún ̀ṣẹ̀ wa, a dìde nítorí ìdáláre wa.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-