Publicidade

Romanos 6

Ikú ẹsẹ̀, iyè nínú Kristi

1 Ǹjẹ́ àwa ó ha ti ? Ṣé àwa ó jókòó nínú ̀ṣẹ̀, oore-ọ̀fẹ́ ba à máa pọ̀ i? 2 a ri! Àwa ẹni ó ti ̀ṣẹ̀, àwa ó ha ṣe láààyè nínú rẹ̀ mọ́? 3 Tàbí ẹyin mọ gbogbo wa ti a ti bamitiisi wa sínú Jesu Kristi ni a ti bamitiisi sínú ikú rẹ. 4 Nítorí náà, a sin wa pẹ̀Kristi nípa ìtẹ̀bọmi si ikú, ó le jẹ́ pe a ti Kristi dìde pẹ̀ògo Baba, àwa pẹ̀gbé ìgbé ayé tuntun.

5 Nítorí ̀yin ti di ̀kan ṣoṣo pẹ̀rẹ̀, àti pẹ̀rẹ̀, nígbà òun . Nísinsin yìí, ń pín ìyè tuntun rẹ̀, ̀yin yóò dìde gẹ́gẹ́ òun náà ti dìde. 6 Gbogbo èrò búburú ọkàn yín ni a kàn mọ́ àgbélébùú pẹ̀rẹ̀. ̀̀ṣẹ̀ ó ń fẹ́ láti máa dẹ́ṣẹ̀ nínú yín ni a ti sọ di aláìlera. Nítorí náà, ara yín ó ń fẹ́ láti máa dẹ́ṣẹ̀ lábẹ́ àkóso ̀ṣẹ̀ mọ́, láti jẹ́ ẹrú fún ̀ṣẹ̀ mọ́. 7 Nítorí nígbà ti di òkú fún ̀ṣẹ̀, a ti gbà yín sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ gbogbo agbára ̀ṣẹ̀. ̀ṣẹ̀ agbára lórí yín mọ́.

8 Nísinsin yìí, àwa pẹ̀Kristi àwa gbàgbọ́ àwa yóò láààyè pẹ̀rẹ̀. 9 Nítorí àwa mọ̀ Kristi ti dìde kúrò nínú òkú. Òun mọ́. Ikú agbára lórí rẹ̀ mọ́. 10 Kristi lẹ́̀kan ṣoṣo, láti ṣẹ́gun agbára ̀ṣẹ̀, ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ó láààyè títí ayé àìnípẹ̀kun ìdàpọ̀ mímọ́ pẹ̀Ọlọ́run.

11 Nítorí náà, ka ara yín òkú ̀ṣẹ̀, ṣùgbọ́n alààyè Ọlọ́run nínú Kristi Jesu. 12 Nítorí náà ṣe jẹ́ ̀ṣẹ̀ jẹ ọba lórí ara kíkú yín ó ba à máa ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́ rẹ̀. 13 ṣe jẹ́ ̀ara yín kan di ohun èlò ohun búburú, nípa ̀ṣẹ̀ dídá. Ṣùgbọ́n fi wọn fún Ọlọ́run pátápátá. Wọ́n ti di ààyè, jẹ́ wọn di ohun èlò ọwọ́ Ọlọ́run, ó wọ́n fún àwọn ìlànà rẹ̀ ó dára. 14 Nítorí ̀ṣẹ̀ yóò tún ipá lórí yín mọ́, nítorí ̀yin lábẹ́ ìdè òfin, ṣe lábẹ́ oore-ọ̀fẹ́.

Ẹrú ìṣòdodo

15 Ǹjẹ́ èyí túmọ̀ , nísinsin yìí, a tẹ̀síwájú láti máa dẹ́ṣẹ̀ láìbìkítà, nítorí ìgbàlà wa dúró nípa òfin mọ́, ṣe nípa gbígba oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run! 16 Àbí ̀yin mọ̀ , ẹnikẹ́ni yan ̀ó fẹ́? yan ̀ṣẹ̀ ti o yọrí si ikú tàbí ìgbọ́ràn ti o yọrí ìdáláre. Ẹnikẹ́ni fi ara yín fún, òun náà ni yóò jẹ́ ̀yín, ̀yin yóò jẹ́ ẹrú rẹ̀. 17 Ṣùgbọ́n ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run , ̀yin ti jẹ́ ẹrú ̀ṣẹ̀ , ̀yin jẹ́ olùgbọ́ran láti ọkàn àpẹẹrẹ ̀kọ́ èyí Ọlọ́run fi yín lọ́wọ́. 18 Nísinsin yìí, ti dòmìnira kúrò lọ́wọ́ ̀yín àtijọ́, èyí í ṣe ̀ṣẹ̀, ti di ẹrú ̀tuntun èyí ni òdodo.

19 Èmi ń sọ̀rọ̀ ènìyàn nítorí àìlera yín. Gẹ́gẹ́ ̀yín ti jọ̀wọ́ àwọn ̀ara yín lọ́wọ́ ẹrú fún ìwà èérí àti ̀ṣẹ̀ inú ̀ṣẹ̀, bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni ̀yin ó jọ̀wọ́ àwọn ̀ara yín lọ́wọ́ nísinsin yìí ẹrú fún òdodo ìwà mímọ́. 20 Nígbà ̀yin jẹ́ ẹrú ̀ṣẹ̀, ̀yin òmìnira òdodo. 21 Àti , kín ni ìyọrísí rẹ̀? Dájúdájú àbájáde rẹ̀ dára. Níwọ́n ìgbà ojú ń ́ nísinsin yìí láti ronú nípa àwọn wọ̀n-ọn-nì o ti máa ń ṣe nítorí gbogbo wọn yọrí ìparun ayérayé. 22 Ṣùgbọ́n báyìí, ti bọ́ kúrò lọ́wọ́ agbára ̀ṣẹ̀, ti di ẹrú Ọlọ́run àwọn ìbùkún rẹ̀ yin ni ìwà mímọ́ àti ìyè nípẹ̀kun. 23 Nítorí ikú ni èrè ̀ṣẹ̀, ṣùgbọ́n ̀bùn Ọlọ́run ni ìyè àìnípẹ̀kun nínú Kristi Jesu Olúwa wa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-