Pular para o conteúdo
Publicidade

Romu 6

5 6.5: 2Kọ 4.10; Kl 2.12. Nítorí ̀yin ti di ̀kan ṣoṣo pẹ̀rẹ̀, àti pẹ̀rẹ̀, nígbà òun . Nísinsin yìí, ń pín ìyè tuntun rẹ̀, ̀yin yóò dìde gẹ́gẹ́ òun náà ti dìde. 6 6.6: Ro 7.24; Kl 2.13.Gbogbo èrò búburú ọkàn yín ni a kàn mọ́ àgbélébùú pẹ̀rẹ̀. ̀̀ṣẹ̀ ó ń fẹ́ láti máa dẹ́ṣẹ̀ nínú yín ni a ti sọ di aláìlera. Nítorí náà, ara yín ó ń fẹ́ láti máa dẹ́ṣẹ̀ lábẹ́ àkóso ̀ṣẹ̀ mọ́, láti jẹ́ ẹrú fún ̀ṣẹ̀ mọ́. 7 6.7: 1Pt 4.1.Nítorí nígbà ti di òkú fún ̀ṣẹ̀, a ti gbà yín sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ gbogbo agbára ̀ṣẹ̀. ̀ṣẹ̀ agbára lórí yín mọ́.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também