Publicidade

Romanos 7

Àpèjúwe kan láti inú ìgbéyàwó

1 ̀yin ha mọ̀, ara: nítorí èmí àwọn ó mọ òfin sọ̀rọ̀ , òfin ipá lórí ènìyàn níwọ̀n ìgbà ó láààyè nìkan? 2 Fún àpẹẹrẹ, nípa òfin a de obìnrin mọ́ ọkọ rẹ̀ níwọ̀n ìgbà ọkọ náà láààyè, ṣùgbọ́n ọkọ rẹ̀ , a u sílẹ̀ kúrò nínú òfin ìgbéyàwó náà. 3 Nígbà náà, ó fẹ́ ọkùnrin mìíràn nígbà ọkọ rẹ̀ láààyè, panṣágà a ó é. Ṣùgbọ́n ọkọ rẹ̀ , ó bọ́ lọ́wọ́ òfin náà, yóò jẹ́ panṣágà ó ọkọ mìíràn.

4 Bẹ́̀ ni ̀yin ará mi, ̀yin pẹ̀ti di òkú òfin nípa ara Kristi, ̀yin ó ẹlòmíràn, àní ẹni náà a dìde kúrò nínú òkú, àwa ó so èso fún Ọlọ́run. 5 Nítorí ìgbà a wa nípa ti ara, ìfẹ́kúfẹ̀́ ̀ṣẹ̀ nípa ti òfin, ma ń ṣiṣẹ́ nínú wa, a ń so èso ó yẹ fún ikú. 6 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, nípa kíkú ohun so pọ̀ tẹ́lẹ̀ , a ti wa sílẹ̀ kúrò nínú òfin, a sin ín ìlànà tuntun ti ̀, í ṣe ìlànà àtijọ́ ìwé òfin gùnlé.

Bíbá ̀ṣẹ̀ wọ ìjàkadì

7 Ǹjẹ́ àwa o ha ti , nígbà náà? Òfin ha ń ṣe ̀ṣẹ̀ ? a i! Ṣùgbọ́n èmi mọ ohun ̀ṣẹ̀ jẹ́, ṣe nípa òfin. Èmi mọ ojúkòkòrò, ṣe òfin ti , "Ìwọ gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò." 8 Ṣùgbọ́n ̀ṣẹ̀ ti ipa òfin ààyè ṣiṣẹ́ onírúurú ìfẹ́kúfẹ̀́ nínú mi. Nítorí láìsí òfin, ̀ṣẹ̀ jẹ́ ikú. 9 Èmi ti láààyè láìsí òfin nígbà kan ; ṣùgbọ́n nígbà òfin , ̀ṣẹ̀ sọjí èmi . 10 Mo ṣàkíyèsí òfin ó yẹ ó ìyè ni ó padà ikú . 11 Nítorí ̀ṣẹ̀ ti ipa òfin ààyè láti tàn jẹ, ó ti ipa òfin ṣe ikú pa mi. 12 Bẹ́̀ ni mímọ́ ni òfin, mímọ́ ni àṣẹ, àti òdodo, àti dídára.

13 Ǹjẹ́ ohun ó dára ha di ikú fún mi ? a i! Ṣùgbọ́n ̀ṣẹ̀, ó farahàn ̀ṣẹ̀, ó ń ti ipa ohun ó dára ṣiṣẹ́ ikú nínú mi, ̀ṣẹ̀ ti ipa òfin di búburú rékọjá.

14 Nítorí àwa mọ̀ ohun ̀ni òfin, ṣùgbọ́n ẹni ti ara ni èmi, a ti sábẹ́ ̀ṣẹ̀. 15 Èmi pàápàá, mọ̀ ohun èmi ń ṣe. Nítorí , ohun mo fẹ́ ṣe gan an n ṣe é, ṣùgbọ́n ohun mo kórìíra ni mo ń ṣe. 16 Ṣùgbọ́n mo ṣe ohun èmi fẹ́, mo gbà òfin dára. 17 Ṣùgbọ́n ̀rọ̀ ṣe yìí í ṣe èmi ni ó ṣe é ṣe ̀ṣẹ̀ ń gbé inú mi. 18 Èmi mọ̀ dájú ohun ó dára kan ń gbé inú mi, àní, nínú ara ̀ṣẹ̀ mi. Èmi fẹ́ ṣe èyí ó dára, ṣùgbọ́n é ṣe. 19 Nítorí ohun èmi ṣe í ṣe ohun rere èmi fẹ́ láti ṣe; rárá, ṣùgbọ́n búburú èmi fẹ́, èyí ni èmi ń ṣe. 20 Nísinsin yìí, mo ń ṣe nǹkan n fẹ́ láti ṣe, í ṣe èmí fúnra mi ni ó ṣe é, ṣe ̀ṣẹ̀ ń bẹ nínú ni ó ṣe é.

21 Nítorí náà, èmi kíyèsi òfin ń ṣiṣẹ́ nínú mi, nígbà èmi fẹ́ ṣe rere, búburú níbẹ̀ pẹ̀mi. 22 Nínú ìjìnlẹ̀ ọkàn mi mo inú dídùn òfin Ọlọ́run; 23 mo òfin mìíràn ń ṣiṣẹ́ nínú ̀ara mi, èyí ń gbógun ti òfin tinú ọkàn mi , èyí ó sọ mi di ẹrú òfin ̀ṣẹ̀ ó ń ṣiṣẹ́ nínú ̀ara mi. 24 Èmi ẹni òsì! Ta ni yóò ha gbà sílẹ̀ lọ́wọ́ ara kíkú yìí? 25 Ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run nípasẹ̀ Jesu Kristi Olúwa wa!

Ǹjẹ́ nítorí náà, èmi fúnra mi jẹ́ ẹrú òfin Ọlọ́run, ṣùgbọ́n nínú ara ̀ṣẹ̀ mo jẹ́ ẹrú fún òfin ̀ṣẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-