Publicidade

Romanos 9

Ọlọ́run yan Israẹli

1 Òtítọ́ ni èmi ń sọ nínú Kristi, èmi ṣèké, ọkàn mi ń jẹ́ mi ̀nínú ̀Mímọ́. 2 mo ìbìnújẹ́ púpọ̀, àti ìkáàánú ìgbà gbogbo ni ọkàn mi. 3 Nítorí mo fẹ́rẹ gbàdúrà èmi tìkára mi kúrò lọ́dọ̀ Kristi nítorí àwọn ará mi, àwọn ìbátan mi nípa ti ara. 4 Àwọn ẹni i ṣe Israẹli; àwọn ẹni ìsọdọmọ í ṣe, àti ògo, àti májẹ̀, àti ìfúnilófin, àti ìsìn Ọlọ́run, àti àwọn ìlérí. 5 ẹni àwọn Baba í ṣe, àti láti ̀dọ̀ àwọn ẹni Kristi ti nípa ti ara, ẹni ó borí ohun gbogbo, Ọlọ́run olùbùkún láéláé. Àmín.

6 Ṣùgbọ́n í ṣe nítorí ̀rọ̀ Ọlọ́run di asán. í í ṣe gbogbo àwọn ó ti inú Israẹli , àwọn ni Israẹli. 7 Bẹ́̀ ni í ṣe , nítorí wọ́n jẹ́ irú-ọmọ Abrahamu, gbogbo wọn ni ọmọ. ̀mìíràn, "Nínú Isaaki ni a ó ti pe irú-ọmọ rẹ̀." 8 Èyí ni , í ṣe àwọn ọmọ nípa ti ara ni ọmọ Ọlọ́run, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ìlérí ni a irú-ọmọ. 9 Nítorí ̀rọ̀ ìlérí ni èyí: "ìwòyí àmọ́dún ni èmi yóò , Sara yóò ọmọ ọkùnrin."

10 í í ṣe kìkì èyí, ṣùgbọ́n nígbà Rebeka pẹ̀lóyún fún ẹnìkan, fún Isaaki baba wa. 11 Nítorí nígbà ì àwọn ọmọ náà, bẹ́̀ ni wọn ì ṣe rere tàbí búburúìpinnu Ọlọ́run nípa ti ìyànfẹ́ ó dúró, 12 í ṣe nípa ti iṣẹ́, ṣe ti ẹni ń penia ti sọ fún un , "̀gbọ́n ni yóò máa sin àbúrò." 13 Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ , "Jakọbu ni mo fẹ́ràn, ṣùgbọ́n Esau ni mo kórìíra."

14 Ǹjẹ́ àwa yóò ha ti ? Àìṣòdodo ha lọ́dọ̀ Ọlọ́run ? a ri! 15 Nítorí ó fún Mose ,

"Èmi ó ṣàánú fún ẹni èmi yóò ṣàánú fún,

èmi yóò ṣe ìyọ́fún ẹni èmi yóò ṣe ìyọ́fún."

16 Ǹjẹ́ bẹ́̀ ni í ṣe ti ẹni ó fẹ́, í í ṣe ti ẹni ń sáré, ṣe ti Ọlọ́run ń ṣàánú. 17 Nítorí ìwé mímọ́ fún Farao , "Nítorí èyí náà ni mo ṣe gbé dìde, èmi ó le fi agbára mi hàn lára rẹ, àti a à le máa ròyìn orúkọ mi gbogbo ayé." 18 Nítorí náà ni ó ṣe ń ṣàánú fún ẹni ó ú, ẹni ó ú a ọkàn le.

19 Ìwọ ó fún mi , "Kín ni ó ha tún ni ? Nítorí ta ni ó ń de ìfẹ́ rẹ lọ́?" 20 Bẹ́̀ kọ́, ìwọ ènìyàn, ni ìwọ ń Ọlọ́run lóhùn? "Ohun a mọ, a ha máa fún ẹni ó mọ ́n , Èéṣe ìwọ fi mọ mi báyìí?’ " 21 Amọ̀kòkò ha ni agbára lórí amọ̀, nínú ìṣù kan náà láti ṣe apá kan nínú ohun èlò ọlá, àti apá kan nínú ohun èlò àìlọ́?

22 Ǹjẹ́ Ọlọ́run fẹ́ fi ìbínú rẹ̀ hàn ń kọ́? ó fẹ́ sọ agbára rẹ̀ di mọ̀, ó sùúrù púpọ̀ fún àwọn ohun èlò ìbínú a ṣe fún ìparun. 23 Àti ó sọ ̀rọ̀ ògo rẹ̀ di mọ̀ lára àwọn ohun èlò àánú ó ti pèsè ṣáájú fún ògo. 24 Àní àwa, ó ti , í ṣe nínú àwọn Júù nìkan, ṣùgbọ́n nínú àwọn Kèfèrí pẹ̀? 25 ó ti pẹ̀Hosea ,

"Èmi ó pe àwọn í ṣe ènìyàn mi, ènìyàn mi,

àti ẹni í ṣe àyànfẹ́ àyànfẹ́.’ "

26 Yóò ṣe,

"ibi ti a gbé ti sọ fún wọn ,

̀yin í ṣe ènìyàn mi,

níbẹ̀ ni a ó gbé wọ́n ọmọ Ọlọ́run alààyè.’ "

27 Isaiah kígbe nítorí Israẹli :

"iye àwọn ọmọ Israẹli iyanrìn Òkun,

apá kan ni ó gbàlà.

28 Nítorí Olúwa yóò ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ lórí ilẹ̀ ayé,

yóò parí rẹ̀, yóò e kúrò òdodo."

29 Àti Isaiah ti tẹ́lẹ̀:

"ṣe Olúwa àwọn Ọmọ-ogun

ti fi irú-ọmọ sílẹ̀ fún wa,

àwa ìbá ti dàbí Sodomu,

a ti sọ dàbí Gomorra."

30 Ǹjẹ́ ni àwa ó ha ? àwọn Kèfèrí, lépa òdodo, ọwọ́ wọn tẹ òdodo, ṣùgbọ́n òdodo ó ti inú ìgbàlà ni. 31 Ṣùgbọ́n Israẹli ti ń lépa òfin òdodo, ọwọ́ wọn tẹ òfin òdodo. 32 Nítorí ni? Nítorí wọn a nípa ìgbàgbọ́, ṣùgbọ́n ẹni nípa iṣẹ́ òfin. Nítorí wọn kọsẹ̀ lára òkúta ìkọ̀sẹ̀ ni. 33 Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ ,

"Kíyèsi, mo gbé òkúta ìkọ̀sẹ̀ kalẹ̀ Sioni

àti àpáta ó wọn ṣubú,

ẹnikẹ́ni ti ó gbà a gbọ́, ojú yóò í."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-