Pular para o conteúdo
Publicidade

Romanos 9

Ọlọ́run yan Israẹli

1 Òtítọ́ ni èmi ń sọ nínú Kristi, èmi ṣèké, ọkàn mi ń jẹ́ mi ̀nínú ̀Mímọ́. 2 mo ìbìnújẹ́ púpọ̀, àti ìkáàánú ìgbà gbogbo ni ọkàn mi. 3 9.3: Ek 32.32.Nítorí mo fẹ́rẹ gbàdúrà èmi tìkára mi kúrò lọ́dọ̀ Kristi nítorí àwọn ará mi, àwọn ìbátan mi nípa ti ara. 4 9.4: Ro 3.2; 8.15.Àwọn ẹni i ṣe Israẹli; àwọn ẹni ìsọdọmọ í ṣe, àti ògo, àti májẹ̀, àti ìfúnilófin, àti ìsìn Ọlọ́run, àti àwọn ìlérí. 5 ẹni àwọn Baba í ṣe, àti láti ̀dọ̀ àwọn ẹni Kristi ti nípa ti ara, ẹni ó borí ohun gbogbo, Ọlọ́run olùbùkún láéláé. Àmín.

6 9.6: Ro 2.28-29. Ṣùgbọ́n í ṣe nítorí ̀rọ̀ Ọlọ́run di asán. í í ṣe gbogbo àwọn ó ti inú Israẹli , àwọn ni Israẹli. 7 9.7: Gẹ 21.12; Hb 11.18.Bẹ́̀ ni í ṣe , nítorí wọ́n jẹ́ irú-ọmọ Abrahamu, gbogbo wọn ni ọmọ. ̀mìíràn, "Nínú Isaaki ni a ó ti pe irú-ọmọ rẹ̀." 8 9.8: Ga 3.29; 4.28.Èyí ni , í ṣe àwọn ọmọ nípa ti ara ni ọmọ Ọlọ́run, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ìlérí ni a irú-ọmọ. 9 9.9: Gẹ 18.10.Nítorí ̀rọ̀ ìlérí ni èyí: "ìwòyí àmọ́dún ni èmi yóò , Sara yóò ọmọ ọkùnrin."

10 9.10: Gẹ 25.21. í í ṣe kìkì èyí, ṣùgbọ́n nígbà Rebeka pẹ̀lóyún fún ẹnìkan, fún Isaaki baba wa. 11 Nítorí nígbà ì àwọn ọmọ náà, bẹ́̀ ni wọn ì ṣe rere tàbí búburúìpinnu Ọlọ́run nípa ti ìyànfẹ́ ó dúró, 12 9.12: Gẹ 25.23.í ṣe nípa ti iṣẹ́, ṣe ti ẹni ń penia ti sọ fún un , "̀gbọ́n ni yóò máa sin àbúrò." 13 9.13: Ml 1.2-3.Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ , "Jakọbu ni mo fẹ́ràn, ṣùgbọ́n Esau ni mo kórìíra."

14 9.14: 2Ki 19.7. Ǹjẹ́ àwa yóò ha ti ? Àìṣòdodo ha lọ́dọ̀ Ọlọ́run ? a ri! 15 9.15: Ek 33.19.Nítorí ó fún Mose ,

"Èmi ó ṣàánú fún ẹni èmi yóò ṣàánú fún,

èmi yóò ṣe ìyọ́fún ẹni èmi yóò ṣe ìyọ́fún."

16 Ǹjẹ́ bẹ́̀ ni í ṣe ti ẹni ó fẹ́, í í ṣe ti ẹni ń sáré, ṣe ti Ọlọ́run ń ṣàánú. 17 9.17: Ek 9.16.Nítorí ìwé mímọ́ fún Farao , "Nítorí èyí náà ni mo ṣe gbé dìde, èmi ó le fi agbára mi hàn lára rẹ, àti a à le máa ròyìn orúkọ mi gbogbo ayé." 18 9.18: Ro 11.7.Nítorí náà ni ó ṣe ń ṣàánú fún ẹni ó ú, ẹni ó ú a ọkàn le.

19 Ìwọ ó fún mi , "Kín ni ó ha tún ni ? Nítorí ta ni ó ń de ìfẹ́ rẹ lọ́?" 20 9.20: Isa 29.16; 45.9.Bẹ́̀ kọ́, ìwọ ènìyàn, ni ìwọ ń Ọlọ́run lóhùn? "Ohun a mọ, a ha máa fún ẹni ó mọ ́n , Èéṣe ìwọ fi mọ mi báyìí?’ " 21 9.21: 2Tm 2.20.Amọ̀kòkò ha ni agbára lórí amọ̀, nínú ìṣù kan náà láti ṣe apá kan nínú ohun èlò ọlá, àti apá kan nínú ohun èlò àìlọ́?

22 9.22: Òw 16.4. Ǹjẹ́ Ọlọ́run fẹ́ fi ìbínú rẹ̀ hàn ń kọ́? ó fẹ́ sọ agbára rẹ̀ di mọ̀, ó sùúrù púpọ̀ fún àwọn ohun èlò ìbínú a ṣe fún ìparun. 23 9.23: Ro 8.29.Àti ó sọ ̀rọ̀ ògo rẹ̀ di mọ̀ lára àwọn ohun èlò àánú ó ti pèsè ṣáájú fún ògo. 24 9.24: Ro 3.29.Àní àwa, ó ti , í ṣe nínú àwọn Júù nìkan, ṣùgbọ́n nínú àwọn Kèfèrí pẹ̀? 25 9.25: Ho 2.23; 1Pt 2.10.ó ti pẹ̀Hosea ,

"Èmi ó pe àwọn í ṣe ènìyàn mi, ènìyàn mi,

àti ẹni í ṣe àyànfẹ́ àyànfẹ́.’ "

26 9.26: Ho 1.10. Yóò ṣe,

"ibi ti a gbé ti sọ fún wọn ,

̀yin í ṣe ènìyàn mi,

níbẹ̀ ni a ó gbé wọ́n ọmọ Ọlọ́run alààyè.’ "

27 9.27: Isa 10.22-23; Gẹ 22.17; Ho 1.10; Ro 11.5; 2Ọb 19.4; Isa 11.11. Isaiah kígbe nítorí Israẹli :

"iye àwọn ọmọ Israẹli iyanrìn Òkun,

apá kan ni ó gbàlà.

28 Nítorí Olúwa yóò ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ lórí ilẹ̀ ayé,

yóò parí rẹ̀, yóò e kúrò òdodo."

29 9.29: Isa 1.9. Àti Isaiah ti tẹ́lẹ̀:

"ṣe Olúwa àwọn Ọmọ-ogun

ti fi irú-ọmọ sílẹ̀ fún wa,

àwa ìbá ti dàbí Sodomu,

a ti sọ dàbí Gomorra."

30 9.30: Ro 3.22; 10.6,20; Ga 2.16; 3.24; Fp 3.9; Hb 11.7. Ǹjẹ́ ni àwa ó ha ? àwọn Kèfèrí, lépa òdodo, ọwọ́ wọn tẹ òdodo, ṣùgbọ́n òdodo ó ti inú ìgbàlà ni. 31 9.31: Isa 51.1; Ro 10.2-3; 11.7.Ṣùgbọ́n Israẹli ti ń lépa òfin òdodo, ọwọ́ wọn tẹ òfin òdodo. 32 9.32: 1Pt 2.8.Nítorí ni? Nítorí wọn a nípa ìgbàgbọ́, ṣùgbọ́n ẹni nípa iṣẹ́ òfin. Nítorí wọn kọsẹ̀ lára òkúta ìkọ̀sẹ̀ ni. 33 9.33: Isa 28.16; Ro 10.11.Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ ,

"Kíyèsi, mo gbé òkúta ìkọ̀sẹ̀ kalẹ̀ Sioni

àti àpáta ó wọn ṣubú,

ẹnikẹ́ni ti ó gbà a gbọ́, ojú yóò í."

Veja também