Publicidade

Rute 3

Rutu àti Boasi ilẹ̀ ìpakà

1 ọjọ́ kan, Naomi, ìyá ọkọ Rutu fún un , "Ọmọbìnrin mi, ǹjẹ́ yẹ èmi ilé ọkọ mìíràn, níbi wọn yóò ti le è máa tọ́rẹ? 2 ó, Boasi ọkùnrin ìwọ àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ ṣiṣẹ́, í ṣe ìbátan wa, yóò láti fẹ́ ọkà barle ilẹ̀ ìpakà rẹ̀ àṣálẹ́ yìí. 3 Wẹ̀, o fi ìpara olóòórùn dídùn pa ara rẹ, o wọ aṣọ rẹ ó dára jùlọ, o lọ ilẹ̀ ìpakà ó gbé ń pa ọkà, ṣùgbọ́n ṣe jẹ́ ó mọ̀ o níbẹ̀ títí yóò fi jẹ yóò mu tán. 4 í dájú o mọ ibi ó sùn , lẹ́yìn ìgbà ó ti sùn, lọ o ṣí aṣọ ìbora rẹ̀ níbi ẹsẹ̀ rẹ̀ sókè o sùn ibi ẹsẹ̀ náà. Òun yóò sọ ohun ìwọ yóò ṣe fún ."

5 Rutu fèsì , "Gbogbo ohun ìwọ sọ fún mi ni èmi yóò ṣe." 6 Bẹ́̀ ni Rutu lọ ilẹ̀ ìpakà ó ṣe gbogbo ohun ìyá ọkọ rẹ̀ sọ fún un, o ṣe.

7 Nígbà Boasi parí jíjẹ àti mímu tán, ọkàn rẹ̀ kún fún ayọ̀. Ó lọ, ó dùbúlẹ̀ ̀yìn ọkà wọ́n kójọ. Rutu yọ́ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ lọ ibẹ̀, ó ṣí aṣọ ẹsẹ̀ rẹ̀ sókè, ó sùn ibi ẹsẹ̀ rẹ̀. 8 Ó ṣe nígbà ọkùnrin náà tají àárín òru, ̀á, ó ara padà, ó ṣàkíyèsí obìnrin kan ó sùn ibi ẹsẹ̀ rẹ̀.

9 Ó béèrè , "Ta ni ìwọ í ṣe?"

Rutu fèsì , "Èmi ni Rutu, ìránṣẹ́bìnrin rẹ. Da etí aṣọ rẹ , nítorí ìwọ ni ìbátan ó le è padà."

10 Boasi fún un , "Olúwa bùkún fún , ọmọbìnrin mi. Ìfẹ́ o fihàn ti pọ̀ ju ti àtẹ̀yìnwá lọ, ó ti jẹ́ ìwọ lọ láti àwọn ̀dọ́mọkùnrin bóyá ọlọ́rọ̀ tàbí tálákà. 11 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ìwọ ọmọbìnrin mi, bẹ̀. Èmi yóò ṣe ohun gbogbo o béèrè fún . Gbogbo ènìyàn ni ó mọ̀ ́n obìnrin oníwà rere. 12 Nítòótọ́ ni mo èmi jẹ́ ìbátan ó súnmọ́ , ṣùgbọ́n ìbátan kan ó súnmọ́ ju ti tèmi lọ. 13 Dúró síbí títí ilẹ̀ yóò fi mọ́, ó di òwúrọ̀ ọkùnrin náà ṣe tan láti ṣe ìràpadà, ó dára ó ṣe bẹ́̀, bẹ́̀ kọ́, Olúwa ti ń bẹ láààyè nígbà náà ni èmi yóò ṣe ìràpadà, sùn ìhín títí ilẹ̀ yóò fi mọ́."

14 Ó sùn ẹsẹ̀ rẹ̀ títí di òwúrọ̀, ṣùgbọ́n ó dìde òwúrọ̀ kùtùkùtù ẹnìkínní le è ẹnìkejì mọ̀. Boasi sọ fún un , "ṣe jẹ́ ó di mọ̀ obìnrin kan ilẹ̀ ìpakà."

15 Ó tún fún un , "aṣọ ìborùn rẹ o bora, o tẹ̀ sílẹ̀." Rutu ṣe bẹ́̀, Boasi wọn òsùwọ̀n ọkà barle mẹ́i, ó gbé e ú. Nígbà náà ni ó padà ìlú.

16 Nígbà Rutu ilé Naomi ìyá ọkọ léèrè , "Báwo ni ó ti ọmọbìnrin mi?"

Nígbà náà ni ó sọ gbogbo ohun ọkùnrin náà ṣe fún un fún ìyá ọkọ rẹ̀. 17 Ó fi kún un , "Ó sọ fún mi , ṣe padà ̀dọ̀ ìyá ọkọ rẹ ọwọ́ òfo, nítorí náà, ó fún mi ìwọ̀n ọkà barle mẹ́.’ "

18 Naomi fún un , "Dúró, ọmọbìnrin mi títí ìwọ yóò fi mọ ohun gbogbo yóò ti , nítorí ọkùnrin náà sinmi títí ̀rọ̀ náà yóò fi yanjú lónìí."

Veja também

Rute
Ver todos os capítulos de Rute
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-