Pular para o conteúdo
Publicidade

Rutu 4

14 Àwọn obìnrin fún Naomi , "Ìyìn ni fún Olúwa fi sílẹ̀ òní yìí láìní ìbátan, Olùràpadà. ọmọ náà di olókìkí Israẹli. 15 Yóò tún ayé rẹ ṣe, yóò dáàbò ́ ọjọ́ ogbó rẹ. Nítorí ìyàwó ọmọ rẹ, èyí ó sàn fún ju ọmọkùnrin méje lọ, ó fẹ́ràn rẹ ni ó ọmọ yìí fún."

16 Naomi gbé ọmọ náà orí ẹsẹ̀ rẹ̀, ó ń tọ́rẹ̀. 17 Àwọn obìnrin àdúgbò , "A ọmọkùnrin kan fún Naomi." Wọ́n pe orúkọ rẹ̀ Obedi. Òun ni baba Jese í ṣe baba Dafidi.

Veja também

Rute
Ver todos os capítulos de Rute