Pular para o conteúdo
Publicidade

Anjos

Por Bíblia Online

Os anjos são seres celestiais criados por Deus para servir, adorar e executar seus propósitos. A Bíblia revela anjos mensageiros, guerreiros e protetores ao longo de toda a história redentora.

Ṣùgbọ́n nígbà ó ro èrò yìí tán, angẹli Olúwa yọ i ojú àlá, ó , "Josẹfu, ọmọ Dafidi, fòyà láti fi Maria ṣe aya rẹ, nítorí oyún ó nínú rẹ̀ láti ọwọ́ ̀Mímọ́ ni.

Nígbà náà ni angẹli náà fún àwọn obìnrin náà , "ṣe bẹ̀. Mo mọ̀ ̀yin ń Jesu a kàn mọ́ àgbélébùú. Ṣùgbọ́n níhìn-ín. Nítorí ó ti jíǹde, gẹ́gẹ́ òun ti . wọlé wo ibi ti wọ́n tẹ́ .

Ìwọ mọ̀ èmi béèrè lọ́wọ́ Baba mi ó fún mi ju légíónì angẹli méjìlá? Òun yóò fi wọ́n ránṣẹ́ lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀.

Ṣùgbọ́n angẹli náà fún un , "bẹ̀, Maria, nítorí ìwọ ti ojúrere lọ́dọ̀ Ọlọ́run. Ìwọ yóò lóyún nínú rẹ, ìwọ ó ọmọkùnrin kan, ìwọ ó pe orúkọ rẹ̀ Jesu.

Angẹli náà fún wọn , "bẹ̀: ó, mo ìyìnrere ayọ̀ ńlá fún yín , yóò ṣe ti ènìyàn gbogbo.

"Ògo ni fún Ọlọ́run lókè ̀run,

àti ayé àlàáfíà, ìfẹ́ inú rere ènìyàn."

Mo fún yín, gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni ayọ̀ ń bẹ níwájú àwọn angẹli Ọlọ́run lórí ẹlẹ́ṣẹ̀ kan ó ronúpìwàdà."

wọ́n ti tẹjúmọ́ ojú ̀run ó ti ń lọ sókè, lójijì, àwọn ọkùnrin méjì ó wọ aṣọ funfun dúró létí ̀dọ̀ wọn. Wọ́n , "̀yin ara Galili, èéṣe ̀yin fi dúró ̀ ń wo ojú ̀run? Jesu yìí, a gbà sókè ̀run kúrò lọ́wọ́ yín, yóò padà bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ti ó ń lọ ̀run."

Ìparí àwọn ̀rọ̀ ìyànjú náà

ìfẹ́ ará o títí. ṣe gbàgbé láti máa ṣe àlejò; nítorí nípa bẹ́̀ ni àwọn ẹlòmíràn ṣe àwọn angẹli àlejò láìmọ̀.

Ìfẹ́

èmi tilẹ̀ sọ oríṣìíríṣìí èdè ènìyàn àti ti angẹli, n ìfẹ́, mo kàn ń pariwo ago lásán ni tàbí i kimbali olóhùn gooro.

Láìṣiyèméjì, títóbi ohun ìjìnlẹ̀ ìwà-bí-Ọlọ́run:

ẹni a fihàn nínú ara,

a láre nínú ̀,

ti àwọn angẹli ,

a wàásù rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,

a gbàgbọ́ nínú ayé,

a gbà sókè sínú ògo.

Nítorí , Olúwa fúnra rẹ̀ yóò sọ̀kalẹ̀ láti ̀run , pẹ̀ariwo àṣẹ ńlá àti ohùn àwọn angẹli ti àwọn angẹli ti àwọn ti ìpè Ọlọ́run, àwọn òkú nínú Kristi yóò kọ́kọ́ jíǹde. Nígbà náà ni a ó gba àwa ó láààyè sókè nínú àwọsánmọ̀ láti ọwọ́ Olúwa. A ó pẹ̀rẹ̀ títí láéláé.

Ẹni ó ṣẹ́gun, òun náà ni a ó fi aṣọ funfun wọ̀; èmi yóò pa orúkọ rẹ̀ kúrò nínú ìwé ìyè, ṣùgbọ́n èmi yóò jẹ́wọ́ orúkọ rẹ̀ níwájú Baba mi, àti níwájú àwọn angẹli rẹ̀.

Nítorí ó mi lójú gbangba , í ṣe ikú tàbí ìyè, í ṣe àwọn angẹli tàbí ̀èṣù, í ṣe ohun ìgbà ìsinsin yìí tàbí ohun ó ń bọ̀, tàbí àwọn agbára, tàbí òkè, tàbí ̀gbun, tàbí ohunkóhun nínú ìṣẹ̀ni yóò le kúrò nínú ìfẹ́ Ọlọ́run ó ń bẹ nínú Kristi Jesu, Olúwa wa.

Seja o primeiro

Este artigo te tocou? Faça uma oração!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.