Publicidade

Coração quebrantado

Por Bíblia Online

Deus está perto dos que têm o coração quebrantado. A Bíblia consola os aflitos: o sacrifício que Deus aceita é o espírito quebrantado e um coração contrito — jamais desprezará.

Olúwa súnmọ́ etí ̀dọ̀ àwọn oníròbìnújẹ́ ọkàn;

ó gba irú àwọn í ṣe oníròra ọkàn .

Ẹbọ Ọlọ́run ni ìròbìnújẹ́ ọkàn ìròbìnújẹ́ àti ìrora àyà.

Ó wo àwọn ọkàn wọ́n bàjẹ́ sàn

ó di ọgbẹ́ wọ́n.

Ara mi àti ọkàn mi le è kùnà

ṣùgbọ́n Ọlọ́run ni agbára ̀mi

àti ìpín mi títí láé.

Nítorí èyí ni ohun Ẹni gíga àti ọlọ́jùlọ

ẹni ó títí láé, orúkọ rẹ̀ jẹ́ mímọ́:

"Mo ń gbé ibi gíga àti ibi mímọ́,

ṣùgbọ́n pẹ̀ẹni n ó ìròbìnújẹ́ àti ̀ìrẹ̀lẹ̀,

láti sọ ̀onírẹ̀lẹ̀ náà

àti láti sọ ̀oníròbìnújẹ́ n .

í ha á ṣe ọwọ́ mi ṣe nǹkan wọ̀nyí,

bẹ́̀ ni wọ́n ?"

ni Olúwa .

"Eléyìí ni ẹni mo :

ẹni náà ó rẹra rẹ̀ sílẹ̀ ó kẹ́dùn ọkàn rẹ̀,

ó wárìrì ̀rọ̀ mi.

Ọdún ojúrere Olúwa

̀Olúwa Olódùmarè lára mi

nítorí Olúwa ti fi àmì òróró yàn

láti wàásù ìyìnrere fún àwọn tálákà.

Ó ti rán mi láti ṣe àwòtán oníròbìnújẹ́

láti kéde ìdásílẹ̀ fún àwọn ìgbèkùn

àti ìtúsílẹ̀ kúrò nínú òkùnkùn fún àwọn ẹlẹ́wọ̀n,

láti kéde ọdún ojúrere Olúwa

àti ọjọ́ ̀san ti Ọlọ́run wa,

láti tu àwọn ń ṣọ̀fọ̀ nínú,

àti láti pèsè fún àwọn inú wọn bàjẹ́ Sioni

láti wọn ládé ẹwà dípò eérú,

òróró ayọ̀ dípò ̀fọ̀,

àti aṣọ ìyìn dípò ìpòrúru ọkàn.

A ó wọ́n igi óákù òdodo,

irúgbìn Olúwa

láti fi ọláńlá rẹ̀ hàn.

"Alábùkún fún ni àwọn òtòṣì ̀,

nítorí tiwọn ni ìjọba ̀run.

Alábùkún fún ni àwọn ń ṣọ̀fọ̀,

nítorí a ó wọ́n nínú.

Alábùkún fún ni àwọn ọlọ́kàn tútù,

nítorí wọn yóò jogún ayé.

Nítorí ìbànújẹ́ ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run máa ṣiṣẹ́ ìrònúpìwàdà ìgbàlà í àbámọ̀ , ṣùgbọ́n ìbànújẹ́ ti ayé a máa ṣiṣẹ́ ikú. Kíyèsi i, nítorí ohun kan náà yìí a yin banújẹ́ fún ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run, irú ìmúraṣíṣẹ́ ó jáde nínú yín, wíwẹ ara yín mọ́ ń kọ́, ìbànújẹ́ ń kọ́, ìpayà ń kọ́, ìfojúṣọ́ń kọ́, ìtara ń kọ́, ìjẹ́ni-níyà ń kọ́. Nínú ohun àmì kọ̀̀kan yìí ni ̀yin ti fi ara yín hàn aláìlẹ́bi nínú ̀ràn náà.

Òun fún mi , "Oore-ọ̀fẹ́ mi fún , nítorí a sọ agbára mi di pípé nínú àìlera." Nítorí náà tayọ̀tayọ̀ ni èmi ó kúkú máa fi ṣògo nínú àìlera mi, agbára Kristi máa gbé inú mi.

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-