Publicidade

Salmos 147

1 fi ìyìn fún Olúwa.

Nítorí ohun rere ni láti máa kọrin ìyìn Ọlọ́run wa,

ó yẹ láti kọrin ìyìn i!

2 Olúwa kọ́ Jerusalẹmu;

Ó àwọn Israẹli a sọnù jọ.

3 Ó wo àwọn ọkàn wọ́n bàjẹ́ sàn

ó di ọgbẹ́ wọ́n.

4 Ó ka iye àwọn ìràwọ̀

ó pe ̀kọ̀̀kan wọn orúkọ.

5 Títóbi ni Olúwa wa ó pọ̀ agbára

òye rẹ̀ òpin.

6 Olúwa wa pẹ̀àwọn onírẹ̀lẹ̀

bẹ́̀ ni ó rẹ̀ àwọn ènìyàn búburú sílẹ̀.

7 Fi ọpẹ́ kọrin Olúwa

fi ohun èlò orin olókùn yin Ọlọ́run.

8 Ó fi ìkùùkuu bo àwọ̀ sánmọ̀

ó rọ òjò orílẹ̀ ayé

ó koríko lórí àwọn òkè

9 Ó pèsè oúnjẹ fún àwọn ẹranko

àti fún àwọn ọmọ ẹyẹ ìwò ìgbà wọ́n ń .

10 Òun inú dídùn nínú agbára ẹṣin,

bẹ́̀ ni Òun ayọ̀ ̀ṣẹ̀ ọkùnrin

11 Olúwa ni ayọ̀ nínú àwọn ó bẹ̀rẹ̀,

àwọn ó ìrètí nínú àánú rẹ̀.

12 Yin Olúwa, ìwọ Jerusalẹmu;

yin Ọlọ́run rẹ, ìwọ Sioni.

13 Nítorí ó ti ̀ìdábùú ibodè rẹ̀ lágbára,

Òun ti bùkún fún àwọn ọmọ rẹ̀ nínú rẹ

14 Òun jẹ́ àlàáfíà àwọn ẹnu ibodè rẹ̀,

òun fi jéró dáradára tẹ́ lọ́rùn.

15 Òun rán àṣẹ rẹ̀ ayé

̀rọ̀ rẹ̀ sáré tete.

16 Ó fi yìnyín fún ni bi irun àgùntàn

ó fọ́n ìrì dídì eérú

17 Ó rọ òjò yìnyín rẹ̀ òkúta wẹ́wẹ́

ta ni ó dúró níwájú òtútù rẹ̀

18 Ó rán ̀rọ̀ rẹ̀ jáde ó wọn yọ̀

ó afẹ́fẹ́ rẹ̀ fẹ́

ó odò rẹ̀ sàn.

19 Ó sọ ̀rọ̀ rẹ̀ di mọ̀ fún Jakọbu

àwọn òfin àti ìlànà rẹ̀ fún Israẹli.

20 Òun ṣe irú èyí orílẹ̀-èdè kan , ó ṣe ti ìdájọ́ rẹ̀

wọn ko mọ òfin rẹ̀.

fi ìyìn fún Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-