Pular para o conteúdo
Publicidade

Guardar o coração

Por Bíblia Online

Guardar o coração é o mandamento mais urgente de Provérbios. Sobre tudo o que se deve guardar, guarda o teu coração, porque dele procedem as fontes da vida.

Sobre tudo, guarda o coração

O coração é a nascente de tudo — pensamentos, desejos, decisões. Guardá-lo é proteger toda a vida espiritual e emocional.

Ju gbogbo nǹkan tókù lọ, pa ọkàn rẹ mọ́,

nítorí òun ni orísun ìyè.

Ọmọ mi, fi àyà rẹ fún mi,

o jẹ́ ojú rẹ inú dídùn ̀mi.

Àwọn àǹfààní ọgbọ́n mìíràn

Ọmọ mi, ṣe gbàgbé ̀kọ́ mi.

Ṣùgbọ́n pa òfin mi mọ́ ọkàn rẹ.

Nítorí ọjọ́ gígùn, ̀gígùn, àti àlàáfíà,

ni wọn yóò fi kùn un fún .

Ènìyàn rere láti inú yàrá ìṣúra rere ọkàn rẹ̀ ohun rere jáde ; àti ènìyàn búburú láti inú ìṣúra búburú ọkàn rẹ̀ í ohun búburú jáde : nítorí láti inú ̀kúnrẹ́rẹ́ ọkàn ẹnu ti máa sọ jáde.

Coração puro e renovado

Cria em mim um coração puro, ó Deus. Os puros de coração verão a Deus — e o Espírito renova nosso interior.

ọkàn mímọ́ inú mi, Ọlọ́run,

o tún ̀dídúró ṣinṣin ṣe sínú mi.

Alábùkún fún ni àwọn ọlọ́kàn mímọ́,

nítorí wọn yóò Ọlọ́run.

Ọlọ́run, wádìí mi, o mọ ọkàn ;

dán mi , o mọ ìrò inú mi.

ó ó ipa ̀búburú

kan nínú mi ó

fi ẹsẹ̀ mi ̀àìnípẹ̀kun.

Wádìí mi , Ìwọ Olúwa, o dán mi ,

dán àyà àti ọkàn mi ;

nítorí ìfẹ́ ̀ rẹ ó dúró ṣinṣin ń bẹ níwájú mi,

èmí ti rìn nínú òtítọ́ rẹ.

Ìwọ ti dán àyà mi ,

ìwọ bẹ̀ òru, o ti wádìí mi,

ìwọ yóò ohunkóhun èmi ti pinnu ,

ẹnu mi yóò ṣẹ̀.

ó ṣe ti iṣẹ́ ènìyàn nípa ̀rọ̀ ẹnu rẹ,

èmi ti pa ara mi mọ́

kúrò ̀àwọn ìkà.

Ìrìn ti jẹ mọ́ ̀rẹ;

ẹsẹ̀ mi yóò yọ̀.

Ọkàn mi ti múra Ọlọ́run;

ọkàn mi ti múra, èmi ó kọrin, èmi ó si máa kọrin ìyìn.

Guardar com a Palavra

Não vos conformeis com este mundo. A Palavra de Deus guardada no coração nos protege do pecado e nos direciona.

da ara yín pọ̀ mọ́ ayé yìí; ṣùgbọ́n paradà láti di tuntun èrò inú yín, ̀yin ó ìdí ìfẹ́ Ọlọ́run, ó dára, ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà, ti ó .

ṣe jẹ́ ìwé òfin yìí kúrò ẹnu rẹ, máa ṣe àṣàrò nínú u rẹ̀ ̀sán àti òru, ìwọ ó ṣọ́ra láti ṣe gbogbo nǹkan a kọ inú u rẹ̀. Nígbà náà ni yóò dára fún , ìwọ yóò àṣeyọrí.

Èmi pẹ̀gbogbo ọkàn mi

ṣe jẹ́ èmi yapa kúrò nínú àṣẹ rẹ.

Èmi ti pa ̀rọ̀ rẹ mọ́ ọkàn mi

èmi ba à ṣẹ̀ .

Fẹ́ràn Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀gbogbo àyà rẹ àti gbogbo ọkàn rẹ, àti gbogbo agbára rẹ. Àwọn àṣẹ mo fún un yín lónìí gbọdọ̀ máa lóókan àyà yín.

Ó sọ fún un , "gbé ọkàn an yín gbogbo ̀rọ̀ mo ti sọ láàrín yín lónìí, ̀yin pàṣẹ fún àwọn ọmọ yín láti gbọ́rọ̀ àti láti ṣe gbogbo ̀rọ̀ inú òfin yìí.

Vigilância e paz

A paz de Deus guarda nossos corações em Cristo Jesus. Chegai-vos a Deus, purificai os corações — e Ele estará convosco.

ṣe ṣe àníyàn ohunkóhun; ṣùgbọ́n nínú ohun gbogbo, nípa àdúrà àti ̀bẹ̀ pẹ̀ìdúpẹ́, máa fi ìbéèrè yín hàn fún Ọlọ́run. Àti àlàáfíà Ọlọ́run, ó ju ìmòye gbogbo lọ, yóò pa ọkàn àti èrò yín mọ nínú Kristi Jesu.

súnmọ́ Ọlọ́run, òun ó súnmọ́ yín. wẹ ọwọ́ yín mọ́, ̀yin ẹlẹ́ṣẹ̀; ṣe ọkàn yín mímọ́, ̀yin oníyèméjì.

̀yin pẹ̀, sùúrù; fi ọkàn yín balẹ̀, nítorí ìpadà Olúwa dẹ̀dẹ̀.

Àwọn òfin fún ìgbé ayé ìwà mímọ́

Níwọ́n ìgbà a ti yín dìde pẹ̀Kristi máa ṣàfẹ́àwọn nǹkan ń bẹ lókè, níbi Kristi gbé ó jókòó ọwọ́ ̀tún Ọlọ́run.

Seja o primeiro