Publicidade

Josué 1

Olúwa pàṣẹ fún Joṣua

1 Lẹ́yìn ikú u Mose ìránṣẹ́ Olúwa, Olúwa sọ fún Joṣua ọmọ Nuni, olùrànlọ́wọ́ Mose, 2 "Mose ìránṣẹ́ mi ti . Nísinsin yìí, ìwọ àti gbogbo àwọn ènìyàn wọ̀nyí, múra láti kọjá odò Jordani lọ ilẹ̀ Èmi ó fi fún wọn fún àwọn ará Israẹli. 3 Èmi yóò fún un yín gbogbo ibi fi ẹsẹ̀ yín tẹ̀, gẹ́gẹ́ mo ti ṣe ìlérí fún Mose. 4 Ilẹ̀ yín yóò fẹ̀ láti aginjù Lebanoni, àti láti odò ńlá, ti Eufurategbogbo orílẹ̀-èdè Hiti títí ó fi Òkun Ńlá ìwọ̀-oòrùn. 5 yóò ẹnikẹ́ni yóò le è dúró níwájú rẹ ọjọ́ ayé è rẹ gbogbo. mo ti pẹ̀u Mose, bẹ́̀ ni Èmi yóò pẹ̀rẹ, Èmi yóò fi ́ sílẹ̀, bẹ́̀ ni Èmi yóò kọ̀ ́.

6 "Jẹ́ alágbára o àyà le, nítorí ìwọ ni yóò ṣe amọ̀àwọn ènìyàn wọ̀nyí, láti jogún ilẹ̀ mo ti búra fún àwọn baba ńlá a wọn láti fi fún wọn. 7 Jẹ́ alágbára, o àyà le gidigidi. o ṣọ́ra láti pa gbogbo òfin Mose ìránṣẹ́ mi fún mọ́, ṣe kúrò nínú u rẹ̀ ̀tún tàbí òsì, ìwọ ó ṣe rere níbikíbi ìwọ ń lọ. 8 ṣe jẹ́ ìwé òfin yìí kúrò ẹnu rẹ, máa ṣe àṣàrò nínú u rẹ̀ ̀sán àti òru, ìwọ ó ṣọ́ra láti ṣe gbogbo nǹkan a kọ inú u rẹ̀. Nígbà náà ni yóò dára fún , ìwọ yóò àṣeyọrí. 9 Èmi ha ti pàṣẹ fún ? Jẹ́ alágbára o àyà le. ṣe bẹ̀, ṣe rẹ̀wẹ̀, nítorí Olúwa à rẹ yóò pẹ̀rẹ ibikíbi ìwọ ń lọ."

10 Báyìí ni Joṣua pàṣẹ fún olórí àwọn ènìyàn rẹ̀, 11 "la ibùdó , sọ fún àwọn ènìyàn, pèsè oúnjẹ yín sílẹ̀. ìwòyí ̀túnla, ̀yin yóò la Jordani yìí kọjá, láti gba ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run yín fi fún un yín láti .’ "

12 Ṣùgbọ́n Joṣua sọ fún àwọn ará a Reubeni, àwọn ará Gadi àti fún ìdajì ̀Manase , 13 "Rántí àṣẹ Mose ìránṣẹ́ Olúwa pa fún yín: Olúwa Ọlọ́run yín á fún yin ìsinmi, òun yóò fún un yín ilẹ̀ yìí.14 Àwọn ìyàwó yín, àwọn ọmọ yín àti àwọn ẹran ̀sìn yín dúró ilẹ̀ Mose fún un yin ìlà-oòrùn Jordani; ṣùgbọ́n gbogbo àwọn jagunjagun un yín, pẹ̀ìhámọ́ra ogun gbọdọ̀ kọjá síwájú àwọn arákùnrin yín. ̀yin yóò rán àwọn arákùnrin yín lọ́wọ́ 15 títí Olúwa yóò fi fún wọn ìsinmi, gẹ́gẹ́ ó ti ṣe fún un yín, àti títí àwọn pẹ̀yóò fi gba ilẹ̀ náà Olúwa Ọlọ́run yín fi fún wọn. Lẹ́yìn náà, ̀yin padà ilẹ̀ ìní in yín, Mose ìránṣẹ́ Olúwa fi fún un yin agbègbè ìlà-oòrùn ti Jordani."

16 Nígbà náà ni wọ́n Joṣua lóhùn , "Ohunkóhun ìwọ pàṣẹ fún wa ni àwa yóò ṣe, ibikíbi ìwọ rán wa ni àwa yóò lọ. 17 Gẹ́gẹ́ àwa ti gbọ́rọ̀ Mose nínú ohun gbogbo, bẹ́̀ ni àwa yóò máa gbọ́ tìrẹ. Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀rẹ, gẹ́gẹ́ ó ṣe pẹ̀u Mose. 18 Ẹnikẹ́ni ó tàpá ̀rọ̀ rẹ, ṣe ìgbọ́ràn ̀rọ̀ rẹ nínú ohun gbogbo ìwọ yóò pàṣẹ fún wọn, pípa ni a ó pa á. ìwọ à ṣe gírí, ó àyà le!"

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-