Pular para o conteúdo
Publicidade

Homem de Deus

Por Bíblia Online

O homem de Deus é aquele que busca a justiça, a piedade, a fé e o amor. A Bíblia apresenta modelos de homens íntegros que andaram com Deus e marcaram a história.

Características do homem de Deus

O homem de Deus foge das paixões e segue a justiça, a piedade, a fé, o amor, a perseverança e a mansidão.

̀rọ̀ ìyànjú fún Timotiu

Ṣùgbọ́n ìwọ ènìyàn Ọlọ́run, fún nǹkan wọ̀nyí; ó máa lépa òdodo, ìwà-bí-Ọlọ́run, ìgbàgbọ́, ìfẹ́ sùúrù, ìwà tútù.

ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni gan ìgbà èwe rẹ; ṣùgbọ́n ìwọ jẹ́ àpẹẹrẹ fún àwọn ó gbàgbọ́, nínú ̀rọ̀, nínú ìwà híhù, nínú ìfẹ́, nínú ̀, nínú ìgbàgbọ́, nínú ìwà mímọ́.

máa ṣọ́ra, dúró ṣinṣin nínú ìgbàgbọ́, ṣe bi ọkùnrin ó ìgboyà, jẹ́ alágbára. máa ṣe ohun gbogbo nínú ìfẹ́.

Ó ti fihàn ́, ìwọ ènìyàn, ohun ó dára,

àti ohun Olúwa ń béèrè lọ́wọ́ rẹ?

ṣe láti ṣe òtítọ́, o fẹ́ràn àánú,

àti o rìn ìrẹ̀lẹ̀ pẹ̀Ọlọ́run rẹ̀.

Exemplos bíblicos

Noé era justo e íntegro entre seus contemporâneos. Jó era homem reto que temia a Deus e se desviava do mal.

Noa àti ìkún omi

Wọ̀nyí ni ìtàn Noa.

Noa nìkan ni ó jẹ́ olóòótọ́ ènìyàn àti ẹni ó ìgbà ayé rẹ̀, ó fi òtítọ́ Ọlọ́run rìn.

Ìbẹ̀rẹ̀ ìgbé ayé Jobu

Ọkùnrin kan ilẹ̀ Usi, orúkọ ẹni í jẹ́ Jobu; ọkùnrin náà ṣe olóòtítọ́, ó dúró ṣinṣin, ẹni ó bẹ̀Ọlọ́run, ó kórìíra ìwà búburú.

Ọkùnrin kan a rán láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ; orúkọ ẹni ń jẹ́ Johanu. Òun ni a rán fún ̀, ó ṣe ẹlẹ́rìí fún ìmọ́lẹ̀ náà, gbogbo ènìyàn ó gbàgbọ́ nípasẹ̀ rẹ̀.

Olóye ènìyàn gbójú wo ọgbọ́n níwájú,

ṣùgbọ́n ojú aláìgbọ́n ń káàkiri ilẹ̀ ayé.

Viver como filho de Deus

Quem faz a vontade de Deus é eleito. Medite na Palavra e ande nos caminhos do Senhor como verdadeiro discípulo.

Ṣùgbọ́n iye àwọn ó gbà á, àní àwọn náà ó gbà orúkọ rẹ̀ gbọ́, àwọn ni ó fi ̀tọ́ fún láti di ọmọ Ọlọ́run. Àwọn ọmọ í ṣe nípa ̀jẹ̀, tàbí nípa ti ìfẹ́ ara, bẹ́̀ ni í ṣe nípa ìfẹ́ ti ènìyàn, ṣe láti ọwọ́ Ọlọ́run.

Àwa mọ̀ Ọlọ́run í gbọ́ ti ẹlẹ́ṣẹ̀; ṣùgbọ́n ẹnìkan ṣe olùfọkànsìn Ọlọ́run, ó ń ṣe ìfẹ́ rẹ̀, Òun ni ó ń gbọ́ tirẹ̀.

Báwo ni àwọn ̀dọ́ yóò ti ṣe pa ̀rẹ̀ mọ́?

Láti máa gbé ìbámu ̀rọ̀ rẹ.

Èmi pẹ̀gbogbo ọkàn mi

ṣe jẹ́ èmi yapa kúrò nínú àṣẹ rẹ.

Èmi ti pa ̀rọ̀ rẹ mọ́ ọkàn mi

èmi ba à ṣẹ̀ .

Ìyìn ni fún Olúwa;

kọ́ mi àṣẹ rẹ.

Pẹ̀ètè mi èmi tún ṣírò

gbogbo òfin ó láti ẹnu rẹ.

Èmi ń yọ̀ ̀̀rẹ,

ènìyàn ṣe ń yọ̀ nínú ọláńlá.

Èmi ń ṣe àṣàrò nínú ìlànà rẹ

èmi kíyèsi ̀rẹ.

Inú mi dùn àṣẹ rẹ;

èmi yóò gbàgbé ̀rẹ.

Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà,

rìn ìmọ̀ àwọn ènìyàn búburú,

ti dúró ̀àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,

tàbí jókòó ibùjókòó àwọn ẹlẹ́gàn.

Ṣùgbọ́n ayọ̀ inú rẹ̀ nínú òfin Olúwa

àti nínú òfin rẹ̀ ni ó ń ṣe àṣàrò ̀sán àti òru.

Ó dàbí igi a gbìn etí odò ń sàn,

ń so èso rẹ̀ jáde àkókò rẹ̀

ewé rẹ̀ yóò rẹ̀.

Ohunkóhun ó dáwọ́, ni yóò máa yọrí rere.

le bẹ́̀ fún àwọn ènìyàn búburú!

Wọn yóò dàbí ìyàngbò ọkà

afẹ́fẹ́ ń fẹ́ dànù.

Nítorí náà àwọn ènìyàn búburú yóò le è dìde dúró ìdájọ́,

bẹ́̀ ni àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ yóò le è dúró àwùjọ àwọn olódodo.

Nítorí Olúwa ń ṣọ́ ̀àwọn olódodo,

ṣùgbọ́n ̀àwọn ènìyàn búburú ni yóò ṣègbé.

, ìwà yín àtijọ́, ̀yin bọ́ ògbólógbòó ọkùnrin sílẹ̀, èyí ó díbàjẹ́ gẹ́gẹ́ ìfẹ́kúfẹ̀́ ̀tàn; di tuntun ni ̀inú yín; gbé ọkùnrin tuntun ni wọ̀, èyí a ni àwòrán Ọlọ́run nínú òdodo àti ìwà mímọ́ ti òtítọ́.

Seja o primeiro