Publicidade

Miquéias 6

Ọlọ́run pe Israẹli níjà

1 fi etí ohun Olúwa :

"Dìde dúró, bẹ ̀bẹ̀ fún ẹjọ́ rẹ níwájú òkè ńlá;

jẹ́ àwọn òkè kéékèèké gbọ́ ohun ó fẹ́ .

2 "Gbọ́, ìwọ òkè ńlá, ̀sùn Olúwa;

gbọ́, ìwọ ìpìlẹ̀ ilé ayérayé.

Nítorí Olúwa ń àwọn ènìyàn rẹ̀ wíjọ́;

òun yóò Israẹli rojọ́.

3 "̀yin ènìyàn mi, ni mo ṣe fún yín?

Àti nínú ni mo ti yin lágara? mi lóhùn.

4 Nítorí èmi un yín gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti ,

mo yín padà láti ilẹ̀ ẹrú .

Mo rán Mose láti darí yín,

bákan náà mo rán Aaroni àti Miriamu síwájú rẹ̀.

5 Ìwọ ènìyàn mi,

rántí ohun Balaki ọba Moabu gbèrò

àti ohun Balaamu ọmọ Beori dáhùn.

Rántí ìrìnàjò rẹ̀ láti Ṣittimu Gilgali,

ìwọ ba le mọ òdodo Olúwa."

6 ni èmi yóò ha síwájú Olúwa

èmi ó fi tẹ ara mi ba níwájú Ọlọ́run gíga?

èmi ha iwájú rẹ̀ pẹ̀ọrẹ ẹbọ sísun,

pẹ̀ọmọ màlúù ọlọ́dún kan?

7 Ǹjẹ́ Olúwa yóò inú dídùn ẹgbẹgbàarùn-ún àgbò,

tàbí ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ìṣàn òróró?

Èmi yóò ha fi àkọ́mi sílẹ̀ fún ìré-òfin-kọjá mi,

èso inú ara mi fún ̀ṣẹ̀ ọkàn mi?

8 Ó ti fihàn ́, ìwọ ènìyàn, ohun ó dára,

àti ohun Olúwa ń béèrè lọ́wọ́ rẹ?

ṣe láti ṣe òtítọ́, o fẹ́ràn àánú,

àti o rìn ìrẹ̀lẹ̀ pẹ̀Ọlọ́run rẹ̀.

̀ṣẹ̀ Israẹli àti ìjìyà wọn

9 Gbọ́! Ohùn Olúwa kígbe ìlú ńlá náà,

láti jẹ ọlọ́gbọ́n ni láti bẹ̀orúkọ rẹ.

"kíyèsi ̀rẹ̀ gbọ́ ̀àti Ẹni náà ó yàn án.

10 Ǹjẹ́ ìṣúra ìwà búburú ha

ilé ènìyàn búburú síbẹ̀,

àti òsùwọ̀n àìkún ó jẹ́ ohun ìbínú?

11 Ǹjẹ́ èmi ha wọ́n mímọ́

pẹ̀òsùwọ̀n búburú,

pẹ̀àpò òsùwọ̀n ̀tàn?

12 Àwọn ọlọ́rọ̀ inú rẹ̀ kún fún ìwà ipá;

àwọn ń gbé inú rẹ̀ ti ̀rọ̀ èké

àti ahọ́n wọn ń sọ ̀tàn?

13 Nítorí náà ni èmi yóò ṣe ṣàìsàn lílù ́,

láti sọ ́ dahoro nítorí ̀ṣẹ̀ rẹ.

14 Ìwọ yóò jẹun ṣùgbọ́n yóò ;

ìyàn yóò láàrín rẹ.

Ìwọ yóò pamọ́, ṣùgbọ́n ìwọ yóò láìléwu,

nítorí ohun ìwọ pamọ́ ni èmi yóò fi fún idà.

15 Ìwọ yóò gbìn ṣùgbọ́n ìwọ yóò kórè

ìwọ yóò tẹ olifi,

ṣùgbọ́n ìwọ yóò fi òróró rẹ̀ kún ara rẹ;

ìwọ yóò tẹ èso àjàrà, ṣùgbọ́n ìwọ yóò mu wáìnì.

16 Nítorí ìwọ ti pa òfin Omri mọ́,

àti gbogbo iṣẹ́ ilé Ahabu,

ó ti tẹ̀ìmọ̀ràn wọn,

nítorí náà ni èmi yóò ṣe fún ìparun

àti àwọn ènìyàn rẹ fún ìfiṣe ẹlẹ́;

ìwọ yóò ru ̀gàn àwọn ènìyàn mi."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-