Pular para o conteúdo
Publicidade

Justiça

Por Bíblia Online

A justiça é atributo de Deus e vocação do cristão. A Bíblia chama os crentes a buscar a justiça, praticar o que é reto e confiar no Deus que julga justamente.

Buscar a justiça

Buscai primeiro o Reino de Deus e a sua justiça. Quem semeia justiça colherá galardão seguro e duradouro.

Ṣùgbọ́n, kọ́kọ́ ìjọba Ọlọ́run àti òdodo rẹ̀, yóò fi gbogbo àwọn nǹkan wọ̀nyí kún un fún yín pẹ̀.

Ènìyàn búburú gba èrè ìtànjẹ

ṣùgbọ́n ẹni fúnrúgbìn òdodo yóò gba èrè dájú.

Ẹni ó tẹ̀òdodo àti àánú yóò ìyè,

òdodo, àti ọlá.

Ṣíṣe ohun ó dára ó tọ̀

ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà Olúwa ju ẹbọ lọ.

Gbogbo ̀ènìyàn dàbí i ó dára lójú rẹ̀,

ṣùgbọ́n, Olúwa ń díwọ̀n ọkàn.

Ìṣúra a kójọ nípa ìwà búburú èrè,

ṣùgbọ́n òdodo a máa gbani lọ́wọ́ ikú.

Justiça em Cristo

Deus tornou Cristo a nossa justiça. Pela fé somos declarados justos diante de Deus — não por obras, mas pela graça.

Nítorí ó fi í ṣe ̀ṣẹ̀ nítorí wa, ẹni mọ ̀ṣẹ̀kẹ́ṣẹ̀ , àwa di òdodo Ọlọ́run nínú rẹ̀.

Nítorí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run ìgbàlà ti fi ara hàn fún gbogbo ènìyàn. Ó ń kọ́ wa láti sẹ́ àìwà-bí-Ọlọ́run àti ìfẹ́kúfẹ̀́ ayé, a máa àìrékọjá, òdodo àti ìwà-bí-Ọlọ́run ayé ìsinsin yìí,

̀rọ̀ ìyànjú fún Timotiu

Ṣùgbọ́n ìwọ ènìyàn Ọlọ́run, fún nǹkan wọ̀nyí; ó máa lépa òdodo, ìwà-bí-Ọlọ́run, ìgbàgbọ́, ìfẹ́ sùúrù, ìwà tútù.

àkótán, ará, ohunkóhun í ṣe òtítọ́, ohunkóhun í ṣe ̀wọ̀, ohunkóhun í ṣe títọ́ ohunkóhun í ṣe mímọ́, ohunkóhun í ṣe fífẹ́, ohunkóhun ó ni ìròyìn rere, ìwà títọ́ kan , ìyìn kan , máa gba nǹkan wọ̀nyí .

a ṣe tàn yín jẹ; a gan Ọlọ́run: nítorí ohunkóhun ènìyàn fúnrúgbìn, òhun ni yóò .

jẹ́ àárẹ̀ ọkàn wa ṣíṣe rere, nítorí a ó kórè nígbà àkókò , a ṣe àárẹ̀.

Praticar a justiça

O fruto da justiça semeia-se em paz para os que promovem a paz. Os olhos do Senhor estão sobre os justos.

Àwọn ó ń ṣiṣẹ́ àlàáfíà a máa gbin èso àlàáfíà àlàáfíà.

jẹ́wọ́ ̀ṣẹ̀ yín fún ara yín, máa gbàdúrà fún ara yín, a yín láradá. Iṣẹ́ àdúrà olódodo ń ṣe agbára púpọ̀.

súnmọ́ Ọlọ́run, òun ó súnmọ́ yín. wẹ ọwọ́ yín mọ́, ̀yin ẹlẹ́ṣẹ̀; ṣe ọkàn yín mímọ́, ̀yin oníyèméjì.

Nítorí Olúwa fẹ́ràn ìdájọ́ òtítọ́,

kọ àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ sílẹ̀.

Àwọn olódodo ni a ó pamọ́ títí ayérayé,

ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ènìyàn búburú ni a ó kúrò.

Ojú Olúwa ń bẹ lára àwọn olódodo;

etí i rẹ̀ ṣí ẹkún wọn.

Dájúdájú a yóò le ipò padà láéláé:

olódodo ni a ó máa ṣe ìrántí rẹ láéláé.

Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà,

rìn ìmọ̀ àwọn ènìyàn búburú,

ti dúró ̀àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,

tàbí jókòó ibùjókòó àwọn ẹlẹ́gàn.

Èmi pẹ̀gbogbo ọkàn mi

ṣe jẹ́ èmi yapa kúrò nínú àṣẹ rẹ.

Consequências

O Senhor recompensará cada um segundo suas obras. A justiça exalta a nação e traz segurança aos que a praticam.

Ọlọ́run yóò san án fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ iṣẹ́ rẹ̀.

i ẹni ó fi búburú san búburú, ṣùgbọ́n máa lépa èyí í ṣe rere láàrín ara yín àti ènìyàn gbogbo.

Ṣùgbọ́n ̀yin jìyà nítorí òdodo, a ti bùkún yín. "ṣe bẹ̀ìhàlẹ̀ wọn, ṣe kọminú."

̀yin ṣoore fún àwọn ó ṣoore fún yín, ọpẹ́ kín ni ̀yin ? Àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ pẹ̀ń ṣe bẹ́̀ gẹ́gẹ́.

Ìdẹ̀kùn ni fún ènìyàn láti ṣe ìlérí kíákíá

nígbà ó ó máa ro ̀jẹ̀ rẹ̀ .

Seja o primeiro

Este artigo te tocou? Faça uma oração!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.