Publicidade

Salmos 1

1 Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà,

rìn ìmọ̀ àwọn ènìyàn búburú,

ti dúró ̀àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,

tàbí jókòó ibùjókòó àwọn ẹlẹ́gàn.

2 Ṣùgbọ́n ayọ̀ inú rẹ̀ nínú òfin Olúwa

àti nínú òfin rẹ̀ ni ó ń ṣe àṣàrò ̀sán àti òru.

3 Ó dàbí igi a gbìn etí odò ń sàn,

ń so èso rẹ̀ jáde àkókò rẹ̀

ewé rẹ̀ yóò rẹ̀.

Ohunkóhun ó dáwọ́, ni yóò máa yọrí rere.

4 le bẹ́̀ fún àwọn ènìyàn búburú!

Wọn yóò dàbí ìyàngbò ọkà

afẹ́fẹ́ ń fẹ́ dànù.

5 Nítorí náà àwọn ènìyàn búburú yóò le è dìde dúró ìdájọ́,

bẹ́̀ ni àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ yóò le è dúró àwùjọ àwọn olódodo.

6 Nítorí Olúwa ń ṣọ́ ̀àwọn olódodo,

ṣùgbọ́n ̀àwọn ènìyàn búburú ni yóò ṣègbé.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-