Pular para o conteúdo
Publicidade

Legalidades

Por Bíblia Online

A Bíblia reconhece a necessidade de leis e governo civil. Os cristãos são chamados a obedecer às autoridades estabelecidas por Deus, enquanto mantêm a lealdade suprema a Cristo.

Submissão às autoridades

Toda autoridade é instituída por Deus. O cristão é chamado a respeitar as leis, pagar tributos e honrar quem governa.

Ṣíṣe ìgbọ́ràn àwọn aláṣẹ

olúkúlùkù ọkàn ó foríbalẹ̀ fún àwọn aláṣẹ ó ipò gíga. Nítorí àṣẹ kan, ṣe láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ; àwọn aláṣẹ ó , láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ni a ti lànà rẹ̀ . Nítorí ẹni ó tàpá àṣẹ, ó tàpá ìlànà Ọlọ́run; àwọn ẹni ó ba ń tàpá, yóò gba ̀bi fún ara wọn. Nítorí àwọn ìjòyè láti dẹ́rùbà àwọn ń ṣe rere, ṣe àwọn ń ṣe búburú. Ǹjẹ́ ìwọ ha fẹ́ di òmìnira kúrò nínú ̀ẹni ipò àṣẹ. Nítorí náà ṣe èyí ó dára, ìwọ yóò gba ìyìn láti ̀dọ̀ rẹ̀. Nítorí ìránṣẹ́ Ọlọ́run ni i ṣe fún ́ rere. Ṣùgbọ́n ìwọ ń ṣé búburú, máa bẹ̀, nítorí gbé idà náà lásán. Nítorí ìránṣẹ́ Ọlọ́run í ṣe, olùgbẹ̀san láti ṣiṣẹ́ ìbínú lára ẹni ń ṣe búburú. Nítorí náà, ̀yin gbọdọ̀ tẹríba fún àwọn aláṣẹ, í ṣe nítorí ti ìbínú nìkan, ṣùgbọ́n nítorí ̀ọkàn pẹ̀.

Nítorí ìdí èyí, san owó òde pẹ̀, nítorí ìránṣẹ́ Ọlọ́run ni wọ́n, èyí náà ni wọ́n ń bojútó nígbà gbogbo. san ohun ó tọ́ fún ẹni gbogbo: owó òde fún ẹni owó òde í ṣe tirẹ̀: owó bodè fún ẹni owó bodè í ṣe tirẹ̀: ̀fún ẹni ̀í ṣe tirẹ̀; ọlá fún ẹni ọlá í ṣe tirẹ̀.

jẹ gbèsè ìfẹ́

ṣe jẹ ẹnikẹ́ni gbèsè ohun kan, ṣe a fẹ́ ọmọ ẹnìkejì ẹni, nítorí ẹni ó fẹ́ ọmọnìkejì rẹ̀, ó òfin .

ìwà yín láàrín àwọn aláìkọlà dára; , wọ́n ti ń sọ̀rọ̀ yín olùṣe búburú, nípa iṣẹ́ rere yín wọn ó máa kíyèsi, wọ́n máa yin Ọlọ́run lógo lọ́jọ́ ti òun ba bẹ̀ .

máa tẹríba fún gbogbo ìlànà ènìyàn nítorí ti Olúwa, ìbá à ṣe fún ọba tàbí fún olórí. Tàbí fún àwọn baálẹ̀, fún àwọn a rán láti ̀dọ̀ rẹ̀ láti gbẹ̀san lára àwọn ń ṣe búburú, àti fún ìyìn àwọn ń ṣe rere.

Nísinsin yìí sọ fún wa, ni èrò rẹ? Ǹjẹ́ ó tọ́ láti san owó orí fún Kesari tàbí tọ́?"

Ṣùgbọ́n Jesu ti mọ èrò búburú inú wọn, ó , "̀yin àgàbàgebè, èéṣe ti ̀yin fi ń dán mi ? fi owó ẹyọ a fi ń san owó orí kan hàn mi." Wọn dínárì kan fún un, ó bi wọ́n , "Àwòrán ta ni èyí? Àkọlé ?"

Wọ́n dáhùn , "Ti Kesari ni."

"Nígbà náà ni ó fún wọn ," "fi èyí í ṣe ti Kesari fún Kesari, fi èyí ti ṣe ti Ọlọ́run fún Ọlọ́run."

Obrigações legais

Jesus cumpriu obrigações legais, pagou impostos e orientou seus seguidores a obedecer à lei sem comprometer a fé.

Owó tẹmpili

Nígbà Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ Kapernaumu, àwọn agbowó òde ń gba owó idẹ méjì jẹ́ owó tẹmpili tọ Peteru wọ́n i , "Ǹjẹ́ olùkọ́ yín ń san owó tẹmpili?"

Peteru dáhùn , "Bẹ́̀ ni, ó ń san."

Nígbà Peteru wọ ilé láti Jesu sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀, Jesu ni ó kọ́kọ́ sọ̀rọ̀, Jesu i , "ni ìwọ , Simoni? Ǹjẹ́ àwọn ọba ayé ń gba owó orí lọ́wọ́ àwọn ọmọ wọn tàbí lọ́wọ́ àwọn àlejò?"

Peteru dáhùn , "Lọ́wọ́ àwọn àlejò ni."

Jesu tún , "Èyí jẹ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ í san owó òde? Síbẹ̀síbẹ̀, àwa fẹ́ wọn bínú. Nítorí náà, lọ etí Òkun, sọ ìwọ̀ omi. ẹja àkọ́kọ́ kọ́ sókè, ya ẹnu rẹ̀, ̀yin yóò owó idẹ kan níbẹ̀, ki fi fún wọn fún owó orí tèmi àti tirẹ̀."

"̀rẹ làjà kánkán, ẹni ó ń gbé lọ sílé ẹjọ́. Ṣe é nígbà ti ó ̀pẹ̀rẹ, bẹ́̀ kọ́ yóò ́ onídàájọ́ lọ́wọ́, onídàájọ́ yóò àwọn ̀ṣọ́ lọ́wọ́, wọ́n a sọ ́ sínú túbú. Lóòótọ́ ni mo fún , ìwọ yóò jáde kúrò níbẹ̀ títí ìwọ yóò fi san ẹyọ owó kan ó .

Nítorí orúkọ mi, a ó yín lọ síwájú àwọn baálẹ̀ àti àwọn ọba, ẹlẹ́rìí wọn àti àwọn aláìkọlà. Nígbà wọ́n yín, ṣe ṣàníyàn ohun ó sọ tàbí ó ṣe sọ ́. ojú kan náà ni a ó fi ohun ̀yin yóò sọ fún yín.

Ìbí Jesu

Ó ṣe ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, àṣẹ ti ̀dọ̀ Kesari Augustu jáde , a kọ orúkọ gbogbo ayé sínú ìwé. (Èyí ni ìkọ sínú ìwé èkínní a ṣe nígbà Kirene fi jẹ baálẹ̀ Siria.) Gbogbo àwọn ènìyàn lọ láti kọ orúkọ wọn sínú ìwé, olúkúlùkù ìlú ara rẹ̀.

Josẹfu pẹ̀gòkè láti Nasareti ni Galili, ìlú Dafidi Judea, à ń Bẹtilẹhẹmu; nítorí ti ìran àti ìdílé Dafidi í ṣe, láti kọ orúkọ rẹ̀, pẹ̀Maria aya rẹ̀ àfẹ́sọ́, oyún rẹ̀ ti .

Perspectiva divina

As nações são como uma gota no balde diante de Deus. Ele abre portas que nenhuma lei pode fechar.

Nítòótọ́ àwọn orílẹ̀-èdè dàbí i ̀kún omi nínú garawa;

a wọ́n gẹ́gẹ́ eruku lórí ìwọ̀n;

ó wọn àwọn erékùṣù àfi eruku múnúmúnú ni wọ́n.

Níwájú rẹ̀ ni gbogbo orílẹ̀-èdè dàbí ohun ;

gbogbo wọn ohun wúlò

ohun .

Nítorí ìlẹ̀kùn ńlá láti ṣe iṣẹ́ gidi ṣí sílẹ̀ fún , ̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn ̀ń bẹ.

Nítorí náà, Pilatu fún un , "Èmi ni ìwọ fọhùn ? Ìwọ mọ̀ , èmi agbára láti sílẹ̀, èmi agbára láti kàn ́ mọ́ àgbélébùú?"

Jesu a lóhùn , "Ìwọ agbára kan lórí mi, ṣe a fi í fún láti òkè , nítorí náà ẹni ó fi lọ́wọ́ ni ó ̀ṣẹ̀ pọ̀."

Seja o primeiro

Este artigo te tocou? Faça uma oração!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.