Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kọrinti 15

3 15.3: 1Kọ 11.23; 1Pt 2.24; Isa 53.5-12. Nítorí èyí mo gbà ṣáájú ohun gbogbo èmi pẹ̀ti fi e yín lọ́wọ́, Kristi ti nítorí ̀ṣẹ̀ gẹ́gẹ́ ìwé mímọ́ . 4 15.4: Mt 16.21; Sm 16.8-9.Àti a sìnkú rẹ̀, àti ó jíǹde ọjọ́ kẹta gẹ́gẹ́ Ìwé Mímọ́ ; 5 15.5: Lk 24.34; Mt 28.17.àti ó farahàn Peteru, lẹ́yìn èyí, àwọn méjìlá. 6 Lẹ́yìn èyí, ó farahàn àwọn ará o ̀́dẹ́gbẹ̀ta (500) lọ lẹ́̀kan náà; ̀pọ̀ nínú wọn títí fi di ìsinsin yìí, ṣùgbọ́n àwọn díẹ̀ ti sùn.

Veja também