Publicidade

1 Coríntios 2

1 2.1: 1Kọ 1.17. Nígbà èmí tọ̀ yín , ̀yin ará, í ṣe nípa ̀rọ̀ gíga àti ọgbọ́n gíga ni mo fi yín sọ̀rọ̀, nígbà èmi ń sọ̀rọ̀ ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run fún un yín. 2 2.2: Ga 6.14; 1Kọ 1.23.Èmi ti pinnu láti mọ ohunkóhun nígbà ti mo láàrín yín ṣe Jesu Kristi, ẹni a kàn mọ́ àgbélébùú. 3 2.3: Ap 18.1,6,12; 1Kọ 4.10; 2Kọ 11.30.Èmi tọ̀ yín ni àìlera, àti ̀, àti ̀pọ̀lọpọ̀ ìwárìrì. 4 2.4: Ro 15.19; 1Kọ 4.20.Ìwàásù mi àti ̀kọ́ mi, í ṣe nípa ọgbọ́n ènìyàn àti ̀rọ̀ a fi ń ènìyàn lọ́kàn padà, ṣe nípa ìfihàn agbára ̀. 5 2.5: 2Kọ 4.7; 6.7; 1Kọ 12.9.ìgbàgbọ́ yín ó ṣe dúró lórí ọgbọ́n ènìyàn, ṣùgbọ́n ó dúró lórí agbára Ọlọ́run.

Ọgbọ́n láti ̀dọ̀ ̀

6 2.6: Ef 4.13. Ṣùgbọ́n àwa ń sọ̀rọ̀ ọgbọ́n láàrín àwọn a , ṣùgbọ́n í ṣe ọgbọ́n ti ayé yìí tàbí ti àwọn olórí ayé yìí, èyí yóò di asán. 7 2.7: Ro 8.29-30.Bẹ́̀ kọ́, àwa ń sọ̀rọ̀ ọgbọ́n ti Ọlọ́run fi ara sin, ọgbọ́n ó ti fi ara pamọ́, èyí Ọlọ́run ti lànà sílẹ̀ ṣáájú ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé fún ògo wa. 8 2.8: Ap 7.2; Jk 2.1.Èyí ti ẹnikẹ́ni nínú àwọn aláṣẹ ayé yìí mọ̀. Ìbá ṣe wọ́n mọ̀ ́n, wọn tún kan Olúwa ògo mọ́ àgbélébùú. 9 2.9: Isa 64.4; 65.17.Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ :

"Ojú ì ,

etí í gbọ́,

ọkàn ènìyàn ó í mọ̀

ohun Ọlọ́run pèsè sílẹ̀ fún àwọn o fẹ́ ."

10 2.10: Mt 11.25; 13.11; 16.17; Ef 3.3,5. Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ti fi í hàn fún wa nípasẹ̀ ̀rẹ̀.

̀á máa wádìí ohun gbogbo, kódà àwọn àṣírí Ọlọ́run jinlẹ̀ jùlọ. 11 Ta ni nínú ènìyàn ó mọ èrò ọkàn ènìyàn kan, ṣe ̀ènìyàn ó nínú rẹ̀? Bákan náà, ẹni ti ó mọ àwọn èrò Ọlọ́run, ṣe ̀Ọlọ́run fúnra rẹ̀. 12 2.12: Ro 8.15.Àwa gbà ̀ti ayé yìí, ṣe ̀ẹni ó ti ̀dọ̀ Ọlọ́run wa, a òye ohun Ọlọ́run fi fún wa lọ́fẹ̀́. 13 2.13: 1Kọ 1.17.Èyí ni àwa ń , í ṣe èyí a ń kọ nípa ̀rọ̀ ọgbọ́n ènìyàn, ṣùgbọ́n èyí ̀Mímọ́ fi ń kọ ènìyàn, èyí a ń fi ohun ̀ohun ̀. 14 2.14: 1Kọ 1.18; Jk 3.15.Ṣùgbọ́n ènìyàn nípa ti ara gba ohun ti ̀Ọlọ́run wọ̀n-ọn-nì, nítorí wèrè ni wọ́n jásí fún un, òun le mọ̀ wọ́n, nítorí nípa ̀a fi ń wádìí wọn. 15 2.15: 1Kọ 3.1; 14.37; Ga 6.1.Ṣùgbọ́n ẹni ó nípa ti ̀ń wádìí ohun gbogbo, ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni í wádìí rẹ̀.

16 2.16: Isa 40.13; Ro 11.34. "Nítorí ta ni ó mọ ọkàn Olúwa,

ti yóò fi máa kọ́ ?"

Ṣùgbọ́n àwa inú Kristi.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-