Publicidade

1 Coríntios 6

Ìyànjú èdè-àìyedè àwọn onígbàgbọ́

1 6.1: Mt 18.17. ẹnikẹ́ni nínú yín ni èdè-àìyedè ẹnìkejì rẹ̀, ó ha gbọdọ̀ lọ é lẹ́jọ́ níwájú àwọn aláìṣòótọ́ , ṣe níwájú àwọn ènìyàn mímọ́? 2 Ṣé ̀yin mọ̀ àwọn ẹni mímọ́ ni yóò ṣe ìdájọ́ ayé? Ǹjẹ́ ó ba ṣe ìpàṣẹ yín ni a o ti ṣe ìdájọ́ ayé, kín ni ìdí fi yanjú àwọn ̀rọ̀ kéékèèké wọ̀nyí láàrín ara yín. 3 mọ̀ àwa ni a ó ṣe ìdájọ́ àwọn angẹli ? Mélòó mélòó àwọn nǹkan nínú ayé yìí. 4 Nítorí náà, ̀yin ni aáwọ̀ lórí ̀rọ̀ yìí, ǹjẹ́ ó yàn láti gba ìdájọ́ lọ́dọ̀ àwọn ìgbé ayé wọn ń di gígàn nínú ìjọ. 5 Mo sọ èyí ojú yín. Ṣé ó ṣe é ṣe a máa rín ẹnìkan láàrín yín ó gbọ́n níwọ̀n láti ṣe ìdájọ́ èdè-àìyedè láàrín àwọn onígbàgbọ́?

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-