Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Coríntios 6

9 6.9: 1Kọ 15.50.̀yin mọ̀ àwọn aláìṣòótọ́ í yóò jogún ìjọba Ọlọ́run? a máa tàn yín jẹ; í ṣe àwọn àgbèrè, tàbí àwọn abọ̀rìṣà, tàbí àwọn panṣágà, tàbí àwọn ọkùnrin ń ṣe ìṣe obìnrin tàbí àwọn ọkùnrin ń ba ara wọn lòpọ̀ 10 tàbí àwọn olè, tàbí àwọn wọ̀bìà, tàbí àwọn ̀mùtí, tàbí àwọn apẹ̀gàn, tàbí àwọn alọ́nilọ́wọ́gbà ni yóò jogún ìjọba Ọlọ́run. 11 6.11: Ap 22.16; Ro 8.30.Bẹ́̀ ni àwọn ẹlòmíràn nínú yín jẹ́ ; ṣùgbọ́n a ti sọ yín di mímọ́, ṣùgbọ́n a ti yín láre ni orúkọ Jesu Kristi Olúwa, àti nípa ̀Mímọ́ Ọlọ́run wa.

Veja também