Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Coríntios 7

12 7.12: 2Kọ 11.17. Mo fẹ́ fi àwọn ìmọ̀ràn kan kún ún fún un yín, í ṣe àṣẹ láti ̀dọ̀ Olúwa. arákùnrin fẹ́ aya gbàgbọ́, aya náà á fẹ́ dúró ọkọ náà, ọkọ náà í ṣe onígbàgbọ́ gbọdọ̀ kọ̀ ́ sílẹ̀. 13 ó jẹ́ obìnrin fẹ́ ọkọ gbàgbọ́, ṣùgbọ́n ọkọ náà ń fẹ́ obìnrin yìí dúró òun, aya náà gbọdọ̀ kọ̀ ́ sílẹ̀. 14 Nítorí ó ṣe é ṣe a ọkọ gba Kristi gbọ́ súnmọ́ Ọlọ́run nípa aya í ṣe onígbàgbọ́, a le ìyàwó gba Kristi gbọ́ súnmọ́ Ọlọ́run nípa ọkọ í ṣe onígbàgbọ́. ṣe bẹ́̀, àwọn ọmọ wọn yóò jẹ́ aláìmọ́. Ṣùgbọ́n wọn kọ ara wọn sílẹ̀, ó ṣe é ṣe àwọn ọmọ wọn di mímọ́.

Veja também