Publicidade

1 Coríntios 9

Àwọn ̀tọ́ aposteli

1 Èmi ha ni òmìnira ? Èmi ha ń ṣe aposteli ? Èmi ha ti Jesu Olúwa ? ̀yìn ha kọ́ èrè iṣẹ́ mi nínú Olúwa ? 2 ìrònú àwọn ẹlòmíràn, èmi í ṣe aposteli. Dájúdájú aposteli ni mo jẹ́ fún un yín, n ṣe fún àwọn ẹlòmíràn. Nítorí èdìdì iṣẹ́ aposteli mi ni ̀yin jẹ́ nínú Olúwa.

3 Èyí ni ìdáhùn mi àwọn ń béèrè ̀tọ́ aposteli mi. 4 Ṣé a ̀tọ́ láti máa jẹ àti láti máa mu ? 5 Ṣé àwa ̀tọ́ láti máa ìyàwó í ṣe onígbàgbọ́ káàkiri gẹ́gẹ́ àwọn aposteli mìíràn? Àti arákùnrin Olúwa, àti Kefa. 6 Ṣé èmi nìkan àti Barnaba, àwa ha agbára láti máa ṣiṣẹ́ bọ́ ara wa ni?

7 Ta ni ó ṣíṣẹ́ ológun ó sanwó ara rẹ̀? Ta gbin ọgbà àjàrà í jẹ nínú èso rẹ̀? Tàbí ta ń bọ ̀wọ́ ẹran í ì jẹ nínú wàrà ̀wọ́ ẹran? 8 Èmi ha sọ nǹkan wọ̀nyí ènìyàn? Tàbí òfin bákan náà ? 9 Nítorí nínú òfin Ọlọ́run fún Mose, ni a kọ ́ , "Ìwọ gbọdọ̀ di màlúù ti ń tẹ ọkà lẹ́nu." Ǹjẹ́ màlúù ni Ọlọ́run n ṣe ìtọ́rẹ̀ bi? 10 Dájúdájú ó sọ eléyìí fún wa , nítorí wa ni a ṣe kọ̀yìí ẹni ń tulẹ̀ máa tulẹ̀ ìrètí àti ẹni ń pakà ni ìrètí láti ìpín nínú ìkórè. 11 àwa ti fún irúgbìn ohun ti ̀sínú ọkàn yín, ohun ńlá ha ni àwa ó ba ohun ti yín ṣe ti ara? 12 àwọn ẹlòmíràn ̀tọ́ ìrànlọ́wọ́ láti ̀dọ̀ yín, àwa ha kọ́ ni ó tọ́ ?

Ṣùgbọ́n àwa lo agbára yìí ṣùgbọ́n àwa faradà ohun gbogbo, àwa ba à ṣe ìdènà fún ìyìnrere Kristi.

13 Ǹjẹ́ ó e yín Ọlọ́run sọ fún àwọn ó ń ṣiṣẹ́ nínú tẹmpili wọ́n oúnjẹ tàbí àwọn ̀bùn wọ́n fún òun, láti fi ṣe ìtọ́ara wọn? Àti àwọn ń dúró pẹpẹ wọn a máa ṣe àjọpín pẹ̀pẹpẹ. 14 Gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni Olúwa ti fi àṣẹ lélẹ̀ , àwọn ń wàásù ìyìnrere wọn máa jẹ́ nípa ìyìnrere.

15 Síbẹ̀síbẹ̀ n ì ì lo irú àwọn ̀tọ́ wọ̀nyí . Bẹ́̀ ni èmi kọ ìwé yìí láti fi sọ fún un yín , mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ í gbà irú nǹkan bẹ̀ ́ lọ́wọ́ yín. a sọ òtítọ́, ó sàn fún mi láti sínú ebi ju n sọ ògo mo láti wàásù . 16 Nítorí mo ti ń wàásù ìyìnrere, í ṣe ohun mo máa ṣògo . Èmi tilẹ̀ le è ṣe é , a tilẹ̀ sọ mo fẹ́ kọ̀ ́ sílẹ̀. Ègbé ni fún mi mo kọ̀ láti wàásù ìyìnrere. 17 jẹ́ ń wàásù tinútinú mi, mo èrè kan, ṣùgbọ́n ń ṣe tinútinú mi, a ti fi iṣẹ́ ìríjú mi lọ́wọ́. 18 irú ipò báyìí, kín ni yóò jẹ èrè mi ni láti jẹ́? Èrè mi àgbàyanu ayọ̀ mo ń gbà nípa ìwàásù ìyìnrere láìgba owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, láìbéèrè ̀tọ́ mi lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni.

19 mo ti jẹ́ òmìnira ń darapọ̀ mọ́ ẹnikẹ́ni, mo sọ ara mi di ẹrú lọ́dọ̀ gbogbo ènìyàn, láti jèrè ̀pọ̀lọpọ̀ i. 20 Nígbà lọ́dọ̀ àwọn Júù, mo dàbí ̀kan nínú wọn, wọn ba à tẹ́ìwàásù ìyìnrere mi àti ki n le jèrè wọn fún Kristi. Nígbà mo láàrín àwọn lábẹ́ òfin èmi í wọn jiyàn rárá (ó tilẹ̀ jẹ́ èmi lábẹ́ òfin), èmi jèrè àwọn ti ń bẹ lábẹ́ òfin. 21 Nígbà mo láàrín àwọn lábẹ́ òfin, èmi náà yóò dàbí ẹni lábẹ́ òfin (èmi í ṣe aláìlófin Ọlọ́run, ṣùgbọ́n èmí ń bẹ lábẹ́ òfin Kristi), èmi le jèrè àwọn lábẹ́ òfin. 22 Nígbà mo láàrín àwọn aláìlera, èmi náà yóò di aláìlera, èmi jèrè àwọn aláìlera. Mo di ohun gbogbo fún gbogbo ènìyàn, èmi ba à gba díẹ̀ lábẹ́ ó ti ó . 23 Èmi ń ṣe ohun gbogbo nítorí ti ìyìnrere, èmi ó jẹ́ alábápín nínú rẹ̀ pẹ̀yín.

24 ̀yin mọ̀ , olúkúlùkù ẹni ó ipa nínú eré ìje ni ó máa ń sáré, ṣùgbọ́n ẹnìkan ṣoṣo ni ń gba ipò ̀bùn ó ga . Nítorí náà, eré ìje yín ba à le borí. 25 Gbogbo ẹni ó ń sáré ìje a máa lọ nínú ìsẹ́ra-ẹni ó lágbára. Wọ́n ń ṣe èyí láti gba adé ìdíbàjẹ́. Ṣùgbọ́n àwa ń eré ìje tiwa láti fi gba adé ̀run àìdíbàjẹ́ láéláé. 26 Nítorí náà, mo ń eré ìje lọ sójú àmì, í ṣe ẹni ti lójú. ń n borí, í ṣe ẹni ń afẹ́fẹ́ . 27 Ṣùgbọ́n èmi ń ara mi ìjánu, mo ń un abẹ́ ìtẹríba, lẹ́yìn mo ti wàásù fún àwọn ẹlòmíràn, nítorí ohunkóhun, èmi fún rara mi ṣe di ẹni ìtanù fún ̀bùn náà.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-