Pular para o conteúdo
Publicidade

1 João 5

Ìgbàgbọ́ nínú Ọmọ Ọlọ́run

1 5.1: Jh 8.42. Olúkúlùkù ẹni ó gbàgbọ́ Jesu ni Kristi, a i nípa ti Ọlọ́run: àti olúkúlùkù ẹni ó fẹ́ràn. Ẹni ó bi , ó fẹ́ràn ẹni a nípasẹ̀ rẹ̀ pẹ̀. 2 Nípa èyí ni àwa mọ̀ àwa fẹ́ràn àwọn ọmọ Ọlọ́run, nígbà a fẹ́ràn Ọlọ́run, a ń pa òfin rẹ̀ mọ́. 3 5.3: Jh 14.15; 1Jh 2.5; 2Jh 6.Nítorí èyí ni ìfẹ́ Ọlọ́run, àwa pa òfin rẹ̀ mọ́: òfin rẹ̀ nira, 4 5.4: Jh 16.33.nítorí olúkúlùkù ẹni a nípa Ọlọ́run, ó ṣẹ́gun ayé. Èyí ni ìṣẹ́gun ó ṣẹ́gun ayé, àní ìgbàgbọ́ wa. 5 Ta ni ẹni ó ṣẹ́gun ayé, ṣe ẹni ó gbàgbọ́ Ọmọ Ọlọ́run ni Jesu jẹ́?

6 5.6-8: Jh 19.34; 4.23; 15.26. Èyí ni ẹni ó nípa omi àti ̀jẹ̀, Jesu Kristi, í ṣe nípa omi nìkan, ṣe nípa omi àti ̀jẹ̀. Àti ̀ni ó ń jẹ́rìí, nítorí òtítọ́ ni ̀. 7 Nítorí àwọn mẹ́ta ni ó ń jẹ́rìí. 8 ̀, omi, àti ̀jẹ̀: àwọn mẹ́tẹ̀̀ta ni ìṣọ̀kan. 9 5.9: Jh 5.32,36; 8.18.àwa ba ń gba ̀ènìyàn, ̀Ọlọ́run tóbi : nítorí ̀Ọlọ́run ni èyí , Ó jẹ́rìí ti Ọmọ rẹ̀. 10 5.10: 1Jh 1.10.Ẹni ó gba Ọmọ Ọlọ́run gbọ́, ó ni ̀nínú ara rẹ̀; ẹni gba Ọlọ́run gbọ́, ó ti un ni èké; nítorí gba ̀náà gbọ́ Ọlọ́run jẹ́ ti Ọmọ rẹ̀. 11 ̀náà ni èyí Ọlọ́run fún wa ìyè àìnípẹ̀kun, ìyè yìí ń bẹ nínú Ọmọ rẹ̀. 12 5.12: Jh 3.36.Ẹni ó ni Ọmọ, ó ni ìyè; ẹni ni Ọmọ Ọlọ́run, ìyè.

Àwọn àfiyèsí ìparí

13 5.13: Jh 20.31. Nǹkan wọ̀nyí ni mo kọ̀rẹ̀ yín, àní ̀yin ó gba orúkọ Ọmọ Ọlọ́run gbọ́; ̀yin mọ̀ ̀yin ìyè àìnípẹ̀kun, àní fún ̀yin ó gba orúkọ Ọmọ Ọlọ́run gbọ́. 14 5.14: Mt 7.7; 1Jh 3.21.Èyí ni ìgboyà àwa níwájú rẹ̀, àwa béèrè ohunkóhun gẹ́gẹ́ ìfẹ́ rẹ̀, ó ń gbọ́ wa. 15 àwa mọ̀ ó ń gbọ́ wa, ohunkóhun àwa béèrè, àwa mọ̀ àwa ìbéèrè àwa ti béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀ gbà.

16 ẹnikẹ́ni arákùnrin rẹ̀ ń dẹ́ṣẹ̀ í ṣe ikú, òun yóò béèrè, Ọlọ́run yóò fún un ni ìyè, àní, fún àwọn ń dẹ́ṣẹ̀ í ṣe ikú. ̀ṣẹ̀ kan ń bẹ ikú, èmi ki òun gbàdúrà fún èyí. 17 Gbogbo àìṣòdodo ni ̀ṣẹ̀, ̀ṣẹ̀ kan ń bẹ í ṣe ikú.

18 5.18: Jh 17.15; 1Jh 3.9. Àwa mọ̀ ẹnikẹ́ni a nípa ti Ọlọ́run í dẹ́ṣẹ̀: ṣùgbọ́n ẹni a nípa Ọlọ́run a pa ara rẹ̀ mọ́, ẹni búburú fọwọ́ kàn án. 19 Àwa mọ̀ Ọlọ́run ni , àti gbogbo ayé ni ó lábẹ́ agbára ẹni búburú náà. 20 5.20-21: Jh 17.3; If 3.7.Àwa mọ̀ Ọmọ Ọlọ́run , ó fi òye fún wa, àwa mọ ẹni í ṣe òtítọ́, àwa ń bẹ nínú ẹni í ṣe òtítọ́, àní, nínú Ọmọ rẹ̀, Jesu Kristi. Èyí ni Ọlọ́run òtítọ́, àti ìyè àìnípẹ̀kun.

21 ̀yin ọmọ mi, pa ara yín mọ́ kúrò nínú òrìṣà.

Veja também