Publicidade

1 Pedro 1

1 Peteru, aposteli Jesu Kristi,

àwọn àyànfẹ́ Ọlọ́run, ti wọ́n ń ṣe àtìpó àgbáyé, tiwọn káàkiri Pọntu, Galatia, Kappadokia, Asia, àti Bitinia, 2 àwọn ẹni a ti yàn gẹ́gẹ́ ìmọ̀tẹ́lẹ̀ Ọlọ́run Baba, nípa ìsọdimímọ́ ̀, ìgbọ́ràn àti ìbùwọ́n ̀jẹ̀ Jesu Kristi:

oore-ọ̀fẹ́ àti àlàáfíà máa fún yín.

Ìyìn Ọlọ́run fún ìrètí láààyè

3 Ìyìn yẹ Ọlọ́run àti Baba Jesu Kristi Olúwa wa! Ẹni ó tún wa gẹ́gẹ́ àánú ńlá rẹ̀ sínú ìrètí ààyè nípa àjíǹde Jesu Kristi kúrò nínú òkú, 4 àti sínú ogún àìdíbàjẹ́, àti àìlábàwọ́n, àti èyí í ṣá, a ti fi pamọ́ ni ̀run yin, 5 ẹyin a ń pamọ́ nípa agbára Ọlọ́run nípa ìgbàgbọ́ si ìgbàlà, a múra láti fihàn ìgbà ìkẹyìn. 6 yọ̀ nínú èyí púpọ̀, ó tilẹ̀ jẹ́ pe nísinsin yìí fún ìgbà díẹ̀, níwọ̀n ó ti yẹ, a ti fi ̀pọ̀lọpọ̀ ìdánwò yín nínú jẹ́. 7 Àwọn wọ̀nyí wáyé ki ìdánwò ìgbàgbọ́ yín ó ni iye lórí ju wúrà, ti ń ṣègbé lọ, ó tilẹ̀ jẹ́ iná ni a fi ń dán an , yọrísí ìyìn àti ògo àti ọlá ni ìgbà ìfarahàn Jesu Kristi. 8 Ẹni ̀yin fẹ́ láìrí, ẹni ̀yin gbàgbọ́, ó tilẹ̀ jẹ́ i nísinsin yìí ̀yin ń yọ ayọ̀ a fi ẹnu sọ, ó kún fún ògo; 9 ẹyin ń gba ìlépa ìgbàgbọ́ yín, àní ìgbàlà ọkàn yín.

10 ti ìgbàlà yìí, àwọn wòlíì wọ́n sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa oore-ọ̀fẹ́ ó tọ̀ yín , wọ́n wádìí jinlẹ̀ lẹ́sọ̀ lẹ́sọ̀. 11 Wọ́n ń wádìí ìgbà wo tàbí irú à wo ni ̀Kristi ó nínú wọ́n ń tọ́ka , nígbà ó jẹ́rìí ìyà Kristi àti ògo yóò tẹ̀e. 12 Àwọn ẹni a fihàn fún, í ṣe fún àwọn tìkára wọn, ṣe fún àwa ni wọ́n ṣe ìránṣẹ́ ohun wọ̀n-ọn-nì, a ti ròyìn fún yin nísinsin yìí, láti ̀dọ̀ àwọn ti ń wàásù ìyìnrere náà fún yín nípasẹ̀ ̀Mímọ́ a rán láti ̀run; ohun àwọn angẹli ń fẹ́ láti .

jẹ́ mímọ́

13 Nítorí náà, múra ọkàn yín sílẹ̀, ara yín ìjánu, fi ìrètí yín kíkún oore-ọ̀fẹ́, èyí a ń mu bọ̀ fún yin ni ìgbà ìfarahàn Jesu Kristi. 14 àwọn ọmọ ń gbọ́rọ̀, ma ṣe da ara yín pọ̀ mọ́ ìfẹ́kúfẹ̀́ àìmọ́ yín ti àtijọ́. 15 Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ ẹni o yin ti jẹ mímọ́; bẹ́̀ ni ̀yin náà jẹ mímọ́. 16 Nítorí a ti kọ , "jẹ́ mímọ́: nítorí Èmi jẹ mímọ́!"

17 Níwọ́n ̀yin ti ń pe Baba, ẹni ń ṣe ìdájọ́ gẹ́gẹ́ iṣẹ́ olúkúlùkù láìṣe ojúsàájú, máa lo ìgbà àtìpó yin ni ìbẹ̀. 18 Níwọ̀n ̀yin ti mọ̀ a fi ohun ìdíbàjẹ́ yín padà, fàdákà tàbí wúrà kúrò nínú ìwà asán yín, ̀yin ti jogún láti ̀dọ̀ àwọn baba yín. 19 Ṣùgbọ́n pẹ̀̀jẹ̀ iyebíye, i ti ̀dọ́-àgùntàn ti lábùkù, lábàwọ́n, àní, ̀jẹ̀ Kristi. 20 Ẹni a ti mọ̀ tẹ́lẹ̀ nítòótọ́ ṣáájú ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé, ṣùgbọ́n a fihàn ìgbà ìkẹyìn wọ̀nyí nítorí yín. 21 Àní ̀yin o tipasẹ̀ rẹ̀ gba Ọlọ́run gbọ́, ẹni ti ó i dìde kúrò nínú òkú, ó fi ògo fún un; ìgbàgbọ́ àti ìrètí yín lọ́dọ̀ Ọlọ́run.

22 Níwọ́n ̀yin ti wẹ ọkàn yin mọ́ nípa ìgbọ́ràn yín òtítọ́ ìfẹ́ ará ti ̀tàn, fẹ́ ọmọnìkejì yín gidigidi láti ọkàn . 23 a ti tún yín , í ṣe láti inú ìdíbàjẹ́ , ṣe èyí ti í díbàjẹ́ nípa ̀rọ̀ Ọlọ́run ń bẹ láààyè ó dúró. 24 Nítorí ,

"Gbogbo ènìyàn dàbí koríko,

àti gbogbo ògo rẹ̀ bi ìtànná koríko.

Koríko á máa gbẹ ìtànná a máa rẹ̀ dànù,

25 ṣùgbọ́n ̀rọ̀ Olúwa dúró títí láé."

̀rọ̀ náà yìí ni ìyìnrere a wàásù fún yín.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-